Theresa Bowyer
Ìrísí
Ó ka ìwé gbọyè ní London School of Journalism. Bowyer bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ pẹ̀lú Daily Times ní ọdún 1951, lẹ́yìn ọdún méjì lẹ̀nu iṣẹ́ náà , O di olóòtú obìnrin àkọ́kọ́. Ni ọdún 1961, O lọ sí ẹlẹ́ẹ̀kẹjọ ìgbìmọ̀ U. S. National Comọmission fún UNESCO àpérò ní Boston. Lẹ́yìn òpin àpérò náà, Ò lọ sí ìrìn-àjò afẹ́ lọ sí àwọn ìlú Amẹ́ríkà kọ̀kan èyítí àwọn àjọ ti O n rí sí ètò ìpínlẹ̀ sẹ agbáterù rẹ.[1]
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Women's editor of africa is enchanting NY visitor". New York Amsterdam News. December 23, 1961.