Tijjani Zannah Zakariya
Ìrísí
Tijjani Zanna Zakariya, (born on September 27, 1966), jẹ olóṣèlú ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà tinsójú àgbègbè ẹkùn ìdìbò Machina/Nguru/Karasuwa/Yusufari ni ilé igbimọ aṣòfin apapọ láti ìpínlè Yobe[1][2][3][4][5][6]
Ìgbésí àyè ibẹrẹ
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Tijjani no wọn bi ni ọjọ́ kẹtàdínlognon oṣù kẹsàn-án, ọdún 1966. o jẹ ọmọ bíbí ìpínlè Yobe, ni orílè-èdè Nàìjíríà.[2]
Ẹkọ
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Zakariya ni ìwé ẹ̀rí West African Senior School Certificate (WASC).[6]
Itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Yobe lawmaker empowers 1,161 people - Independent News Reporters" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2022-03-07. Retrieved 2025-01-07.
- 1 2 "10th National Assembly Members - Voter - Validating the Office of the Electorate on Representation". orderpaper.ng. Retrieved 2025-01-07.[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
- ↑ "Citizen Science Nigeria". citizensciencenigeria.org (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-01-07.
- ↑ "undefined candidate data for 2023 - Stears Elections". www.stears.co. Retrieved 2025-01-07.[Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
- ↑ "ShineYourEye". www.shineyoureye.org. Retrieved 2025-01-07.
- 1 2 "National Assembly | Federal Republic of Nigeria". nass.gov.ng. Retrieved 2025-01-07.