Tobi Adegboyega
Ìrísí
| Pastor Tobi Adegboyega | |
|---|---|
| Ọjọ́ìbí | Tobi Adegboyega 11 Oṣù Kọkànlá 1980 Ibadan, Oyo State, Nigeria |
| Orílẹ̀-èdè | Nigerian |
| Iléẹ̀kọ́ gíga | Ogun State University |
| Iṣẹ́ | Pastor, televangelist |
| Title | Founder of SPAC Nation |
| Alábàálòpọ̀ | Lucy Oluwatosin Odetola (m. 2011) |
| Àwọn olùbátan | John Boyega (cousin) |
| Website | nxtionfamily.org/about-us |
Tóbi Adégbóyèga (tí wọ́n bí lọ́jọ́ 11 oṣù November ọdún 1980) jẹ́ òjíṣẹ́ Ọlọ́run ọmọ Nigeria.[1] Òun ni olùdásílẹ̀ ìjọ Salvation Proclaimers Anointed Church (SPAC Nation, tí a wá padà mọ̀ sí ìjọ NXTION Family), èyí ìjọ pentecostal àná[2] tó fìgbà kan wà ní London, lórílẹ̀-èdè England.
Àwọn Ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ Pulse Nigeria (21 December 2019). "'We are non-partisan but we'll support aspirations of our members as permitted by law' – says SPAC Nation's Pastor Adegboyega". Pulse Nigeria. https://www.pulse.ng/news/metro/we-are-non-partisan-but-well-support-aspirations-of-our-members-as-permitted-by-law/2257c49. Retrieved 22 May 2020.
- ↑ "Church group wound-up in court". 17 June 2022. Archived from the original on 14 May 2023. https://web.archive.org/web/20230514070018/https://www.gov.uk/government/news/church-group-wound-up-in-court.