University of Offa
| University of Offa | |
|---|---|
| Established | 2021 |
| Type | Private |
| Students | 3,000 |
| Location | Offa, Kwara State, Nigeria |
| Website | https://www.unioffa.edu.ng |
Yunifásítì Ìlú Òffà jẹ ilé ìwé aladani, ti ìjọba àpapò orílè-èdè Nàìjíríà fi owó sì idasile rẹ ni ìlù Offa, ni ìjọba ìbílè Ọfà, ni ìpínlè Kwara, ni orílè-èdè Nàìjíríà. Ilé ẹ̀kọ́ gíga ní ìjọba àpapò n mọ́jú tó láti owo ẹka ìjọba àpapò nípa eto ẹ̀kọ́ ni orílè-èdè Nàìjíríà ti a mon sì Federal Ministry of Education ti o sí gbá ìwé ẹ̀rí idasile láti Ẹka àwùjọ ti o n bójú tó ìdásílẹ̀ àti ìṣàkóso ilé ẹ̀kọ́ gíga Yunifásítì ni orílè-èdè Nàìjíríà eléyìí ti a mon sì National Universities Commission (NUC).[1][2]
Ile ẹ̀kọ́ náà ni Ààrẹ orílè-èdè Nàìjíríà nígbà náà Muhammadu Buhari buwolu ìwé idasile rẹ, pẹ̀lú àwọn ilé ìwé gíga ogún ti o jẹ tí aladani ni orílè-èdè Nàìjíríà ni ọjọ kẹta oṣù kejì ọdún 2021.[3][4]
Ilé ìwé náà ni ó gbà ìwé ẹ̀rí idasile láti ọwọ àwùjọ tí o n bójútó ẹ̀kọ́ ní orílè-èdè ti a mọ sì Ministry of Education, labẹ ìṣàkóso giwa àgbà ní gbà náà ti o sì tun jẹ Minisita fún ètò ẹ̀kọ́ ni orílè-èdè Nàìjíríà Mallam Adamu Adamu, láti bẹrẹ ètò ẹ̀kọ́ fún ọdún mẹ́ta akọkọ, títí di ìgbà tí wọ́n yo fi gbà ìwé ẹ̀rí wípé wọn yege pẹlu àbójútó lore kórè.[5]
Ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Licensing private universities". Daily Trust (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 27 May 2022. Retrieved 2025-08-07.
- ↑ "Private Universities | National Universities Commision" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-08-07.
- ↑ "FEC approves 20 new private universities". www.premiumtimesng.com. Retrieved 2025-08-07.
- ↑ May 2021, Samuel Okocha 27. "Licences to expand Nigeria's private higher education sector". University World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-08-07.
- ↑ Erezi, Dennis (2021-04-08). "NUC issues provisional licenses to 20 new private varsities". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2025-08-07.
Láti tún ká síwájú
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- [http:// Official website]