Victoria Gowon
Victoria Gowon | |
|---|---|
| First Lady of Nigeria | |
| In role 19 April 1969 – 29 July 1975 | |
| Head of State | Yakubu Gowon |
| Asíwájú | Victoria Aguiyi-Ironsi |
| Arọ́pò | Ajoke Muhammed |
| Àwọn àlàyé onítòhún | |
| Ọjọ́ìbí | Victoria Hansatu Zakari 22 Oṣù Kẹjọ 1946 Zaria, Northern Region, British Nigeria (now Zaria, Kaduna State, Nigeria) |
| Ọmọorílẹ̀-èdè | Nigerian |
| (Àwọn) olólùfẹ́ | |
Victoria Hansatu Gowon (tí wọ́n bí ní ọjọ́ kejìlélógún oṣù Kẹjọ ọdún 1946) jẹ́ nọ́ọ̀sì àti ìyàwó Ààrẹ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà ẹlẹ́ẹ̀kẹta. Òun ni ìyàwó General Yakubu Gowon, ẹni tó jẹ́ Olórí ilẹ̀ Nàìjíríà láti ọdún 1966 wọ 1975.[1][2]
Ayé rẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Wọ́n bí Victoria Hansatu Zakari ní ọjọ́ kejìlélógún oṣụ̀ Kẹjọ ọdún 1946 sínú ìdílé Malam Walter Bala, ẹni tó jẹ́ òṣìṣẹ́ ìjọba àti Lydia Fati Zakari, ní ìlú Zaria.[3][4] Ó gba ẹ̀tò ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ àti girama ní Zaria àti Kaduna. Ó parí ètò ẹ̀kọ́ girama rẹ̀ ní ọdún 1964.[4] Ó lọ sí school of Nursing ní University College Hospital, Ibadan, tí ó sì gba ìwé-ẹ̀rí rẹ̀ ní oṣù Keje ọdún 1968.[5] Ìgbéyàwó rẹ̀ pẹ̀lú Yakubu Gowon wáyé lásìkò Ogun abẹ́lẹ̀ ti ilẹ̀ Nàìjíríà ní ọjọ́ kọkàndínlógún oṣù Kẹrin ọdún 1969, ní Cathedral Church of Christ, Lagos.[6][7]
Ó máa ń ṣe ìfarahàn ní gbangba nítorí Yakubu Gowon máa ń ṣe iṣẹ́ rẹ̀ papọ̀.[8]
Ìmúra rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìyàwó Ààrẹ wà níwọ̀ntúnwọ̀nsì, ó sì máa ń wọ àwọn aṣọ ìbílẹ̀ lọ́pọ̀ ìgbà.[9][10]
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ Okon-Ekong, Nseobong (2010-10-02). "Nigeria: First Ladies - Colourful Brilliance, Gaudy Rays". Thisday (AllAfrica.com). http://allafrica.com/stories/201010040212.html.
- ↑ "First Ladies of style". Punch Newspapers (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2017-10-01. Retrieved 2021-07-31.
- ↑ Obasi, Emeka (2017-10-07). "Of Flora, Victoria and Mariam". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-07-30.
- 1 2 (in en) NewAfrican Life. IC Publications. 1990. https://books.google.com/books?id=2uIMAQAAMAAJ&q=%22ajoke+muhammed%22.
- ↑ Admin (2020-11-20). "GOWON,(Dr) Victoria Hansatu". Biographical Legacy and Research Foundation (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-07-30.
- ↑ Obasi, Emeka (2017-10-07). "Of Flora, Victoria and Mariam". Vanguard News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-07-30.
- ↑ Oluleye, Kehinde (2019-11-08). "Famous, long lasting monogamous MARRIAGES". The Nation (Nigeria) (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-07-30.
- ↑ Okon-Ekong, Nseobong (2010-10-02). "Nigeria: First Ladies - Colourful Brilliance, Gaudy Rays". Thisday (AllAfrica.com). http://allafrica.com/stories/201010040212.html.
- ↑ "First Ladies of style". Punch Newspapers (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2017-10-01. Retrieved 2021-07-31.
- ↑ "Nigeria@60: Life & style of First Ladies". Punch Newspapers (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2020-09-27. Retrieved 2021-07-31.