Vincent Eze Ogbulafor
Ìrísí
Vincent Eze Ogbulafor (tí a bí ni ọjọ kẹrinlélógún oṣù kàrún ọdún 1949 [1] – Ti oku ni ọjọ kẹfà oṣù kẹwa ọdún 2022) jẹ olóṣèlú ọmọ Nàìjíríà.
O jẹ alága tẹlẹ ti People's Democratic Party . Ṣáájú ipo yii, o jẹ Akọ̀wé Orílẹ-èdè ti ẹgbẹ naa. [2] O fi ipo rẹ silẹ gẹgẹ bi alaga lẹhìn ti wọn fi ẹsun kan nípa aibikita owo nígbà ti o wà lóri ipò minisita. [3]
O jẹ ọmọ ọba Olokoro, Umuahia South, ìjọba ìbílẹ̀ ipinle Abia . [2]
Ogbulafor kú ni ọjọ kẹfà Oṣu Kẹwa Ọdun 2022, ni ẹni ọdun 73. [4]
Awọn itọkasi
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ https://www.thecable.ng/vincent-ogbulafor-former-pdp-chairman-is-dead/amp
- 1 2 "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2005-11-23. Retrieved 2025-08-18.
- ↑ http://allafrica.com/stories/201005130799.html
- ↑ https://www.thisdaylive.com/index.php/2022/10/08/former-pdp-national-chairman-vincent-ogbulafor-is-dead/