Wọlé Ṣóyínká
| Wole Soyinka Àdàkọ:Postnominals | |
|---|---|
Soyinka in 2018 | |
| Ọjọ́ìbí | Akinwande Oluwole Babatunde Soyinka 13 Oṣù Keje 1934 Abeokuta, British Nigeria |
| Iṣẹ́ | Novelist, playwright, poet |
| Àwọn olùbátan | Ransome-Kuti family |
Akinwande Oluwole Babatunde Soyinka (tí a bí ní ọjọ́ kẹtàlá oṣù keje, ọdún 1934) jẹ́ òǹkọ̀wé Nàìjíríà tí ó gbajúgbajà fún kíkọ eré òntàgé àti ewì. Ó ti kọ ìwé ìtàn àròsọ mẹ́ta, ṣe àkójọpọ̀ mẹ́wàá lórí àwọn ìtàn kéékèèké, àkójọpọ̀ ewì méje, eré òntàgé márùndílọ́gbọ̀n àti ìwé márùn-ún lórí àwọn ìrìn àjò rẹ̀.[1] Ó ti ṣe ọ̀gbufọ̀ iṣẹ̀ méjì, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìròyìn àti ìtàn kéékèèké fún àwọn ìwé ìròyìn púpọ̀. Gbogbo ayé mọ̀ ọ́ gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan lára àwọn akọ̀wé tí ó tóbi jùlọ nílẹ̀ Áfíríkà àti ọ̀kan lára àwọn òǹkọ̀wé eré òntàgé tí ó ṣe pàtàkì jùlọ. Ó gba àmì ẹ̀yẹ ti ọdún 1986 Nobel Prize nínú Literature fún iṣẹ́ rẹ̀ lórí àṣà àti ewì èyí tí ó dá lórí ìṣẹ̀dá eré òntàgé.
A bí sí àwùjọ Anglican ẹbí rẹ̀ ni Aké, Abeokuta, Soyinka bẹ̀rẹ̀ ìrìn àjò ìwé rẹ̀ ní Government College, Ibadan and proceeded to the University College Ibadan. Láàárín kan, ó dára pọ̀ mọ́ àwọn kan láti ṣe olùdásílẹ̀ Pyrate Confraternity. Soyinka kúrò ní Nàìjíríà lọ sí England láti lọ kàwé ni University of Leeds. Láàárín yẹn, ó ṣiṣẹ́ olóòtú fún ìwé ìròyìn tí yunifásítì, èyí tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́, The Eagle, kí ó tó wà di òǹkọ̀wé ni àwọn ọdún 1950s. Ní ìlú ọba, ó bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ ìtàn kéékèèké, ó sì ń ṣe àkọsílẹ̀ fún BBC Lecture series. Ó kọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ eré He wrote many plays which were performed on radios and in theatres in Nigeria and the UK, especially the Royal Court Theatre.
He has been married to his third wife Folake Doherty since 1989. Since 1 September 2022, Soyinka has held the position of Arts Professor of Theatre at New York University Abu Dhabi.
Many of Soyinka's novels and plays are set in Nigeria, reflecting the country’s history, culture, and political struggles. Alongside these works, he produced a wide range of satirical writings that reached a broad audience and enjoyed considerable popularity. He is also an accomplished poet, with numerous individual poems and several published collections to his name. He achieved successes with his plays including The Swamp Dwellers (1958), The Lion and the Jewel (1958), and The Invention, which was one of his early plays to be produced at the Royal Court Theatre. Soyinka wrote a number of other works, including The Interpreters (1965), Season of Anomy (1973), Chronicles from the Land of the Happiest People on Earth, and Harmattan Haze on an African Spring. In July 2024, Bola Tinubu renamed the National Arts Theatre after Soyinka during his 90th birthday.
Ìtọ́kási
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Àkọsílẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ Àṣìṣe ìtọ́kasí: Invalid
<ref>tag; no text was provided for refs named:1