Yekinni Ajileye
Ìrísí
Yekinni Ajileye (1953 - 11th October, 2006) jẹ́ oǹkọ̀tàn, adarí-eré, olóòtú àti òṣèré sinimá àgbéléwò ọmọ Nigeria. Ó di gbajúmọ̀ ìlúmọ̀ọ́ká nígbà tí ó gbé eré Kòtò Ọ̀run jáde lórí telifisan lọ́dún 1989 sí 1992. Lábẹ́ rẹ̀ ni ọpọlọpọ òṣèré mìíràn tí di ìlúmọ̀ọ́ká. Àwọn bí i, Abìjà, Kọ́lédowó, Oyíbóyí, Oladiran Toyin, tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Àbẹ̀ní Agbọ́n, àti ọ̀pọ̀ àwọn òṣèré mìíràn.[1]
Àwọn Ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Yekini Ajileye, Nollywood leading man bows out". A-ARTs. 2011-09-15. Retrieved 2025-11-20.