Abimbola Abolarinwa

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Abimbola Abolarinwa
Ọjọ́ìbíAbimbola Ayodeji Abolarinwa
c. 1979
England, United Kingdom
Orílẹ̀-èdèNigerian
Iṣẹ́
Ìgbà iṣẹ́2006 – present
Àwọn ọmọ2

Abímbọ́lá Ayọ̀dèjì Abọ́lárìnwá (tí wọ́n bí ní 1979), jẹ́ oníṣègùn ọmọ Nàìjíríà. Ó jẹ́ Urọ́lọ́jístì obìnrin àkọ́kọ́ ní Nàìjíríà.[1]

Ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

A bí Abímbọ́lá ní ilẹ̀ gẹ̀ẹ́sì, ìlú Ọba (UK) fún ìyà rẹ̀ tí ó jẹ́ agbẹjọ́rò, bàbá rẹ̀ sí jẹ́ ọmọ ógun òfuurufú àti dókítà onísẹ́ abẹ. Abọ́lárìnwá jẹ́ ọmọ bíbí ìlú Ìlọfà, tí ó jẹ́ ọ̀kan lára agbègbè Ìjọba ìbílẹ̀ Òkè Ẹ̀rọ́ ní Ìpínlẹ̀ Kwara. Ó ka ilé ẹ̀kọ́ alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ ni ilé ẹ̀kọ́ ọmọ ógun òfuurufú Nàìjíríà alákọ̀ọ́bẹ̀rẹ̀ ní Kaduna, ó ṣi parí ilé ẹ̀kọ́ girama rẹ̀ ní ilé ẹ̀kọ́ ọmọ ógun òfuurufú obìnrin tó wà ní ìlú Jos kí ó tó tẹ̀síwájú láti kẹ́kọ̀ọ́ gboyè nínú ìmò ìṣègun ní Yunifásítì Ibadan ni ọdún 2004.[2]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Orakpo, Ebele (24 May 2015). "My job is not family friendly —Abolarinwa, Nigeria’s first female urologist". Vanguard News. http://www.vanguardngr.com/2015/05/my-job-is-not-family-friendly-abolarinwa-nigerias-first-female-urologist/. Retrieved 18 July 2016. 
  2. "LASU VC congratulates Abolarinwa, first Nigerian female Urologist". guardian.ng (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2019-12-19.