Ebun Oloyede Olaiya

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Alhaji Lukman Ẹ̀bùn Olóyèdé Ọláìyá tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Igwe jẹ́ ọmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà àti òṣèré sinimá àgbéléwò. Wọ́n bí Ẹ̀bùn Olóyèdé ní ilú Kẹ́nta, Òkè-Èjìgbò Abẹ́òkúta.

Ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ọláìyá lọ sí ilé ìwé alákọ̀ọ́bọẹ̀rẹ̀ St.Judes ní ìlú Abẹ́òkútaìpínlẹ̀ Ògùn, tí ó sì tún tè síwájú nínú ẹ̀kọ́ rẹ̀ ní ilé ìwé girama (Premier) ní Abẹ́òkúta. Lẹ́yìn tí ó parí èyí ni ó lọ kẹ́kọ̀ọ́ nípa ìbára ẹni sọọ̀rọ̀ ní ilé ẹ̀kọ́ gbogbo-nìṣe tí Moshood Abíọ́lá Òjéèrè ìpínlẹ̀ Ògùn.

Iṣẹ́ rè gẹ́gẹ́ bí òṣèré[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ọláìyá dara pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ òṣèré Musibau Shodimú ní àsìkò ọdún 1970s tí ó wà ní Abẹ́òkúta nígbà náà.[1]

Àwon ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Olaiya Igwe (Lukmon Ebun Oloyede) Biography". LoudestGist Wikipedia. 2016-06-09. Retrieved 2018-11-01.