Adetola Salau

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Àtúnyẹ̀wò ní 03:09, 17 Oṣù Kejìlá 2023 l'átọwọ́ Royalesignature (ọ̀rọ̀ | àfikún)
(ìyàtọ̀) ← Àtúnyẹ̀wò tópẹ́ju | Àtúnyẹ̀wò ìsinsìnyí (ìyàtọ̀) | Àtúnyẹ̀wò tótuntunju → (ìyàtọ̀)
Dr
Adetola Salau
Fáìlì:Tola-Salau.png
The Current Senior Adviser On Education To Kwara State Government and Previously Served as Senior Adviser On Education To Lagos State Government
Ọjọ́ìbí24 Oṣù Kẹfà 1977 (1977-06-24) (ọmọ ọdún 46)
Elizabeth, New Jersey, United States
Orílẹ̀-èdèNigerian
Orúkọ mírànAriyike
Iléẹ̀kọ́ gíga
EmployerKwara State Government
TitleDr

Adetola Ariyike Salau (Abi ni June 24, 1977) òjé Olukọ pẹlu Oloselu Ọmọ bíbí orilede Naijiria osi je olubadamoran pataki nípa ètò ẹkọ sí ijoba Kwara State.

Oti fi igba kan je Olubadamoran Pataki Si Gómìnà ìpínlẹ̀ Èkó Laarin 2020-2023.

Igbeaye Ati Eko

In Elizabeth, New Jersey, Ni wọn ti bi Adetola Salau fún Salau Ademola and Oreoluwa. Ọmọ Ifelodun LGA in Kwara State, ti ori run re je Offa local government in Kwara south.[1][2]

O Gbọye Degree Ni Chemistry Ni Ile-eko Gíga Fordham University Ni Ọdún 1998, àti Syracuse University fun Ẹkọ Master Degrees Ni Engineering Management (2001) and Chemical Engineering (2004). O Parí ekó Doctorate in Curriculum, Instruction and the Science of Learning No State University of New York at Buffalo.[3]

Ise

Adetola ni Olùdámọ̀ràn pàtàkì sí Gomina Kwara Lori Eto Ẹkọ.[4]

Ọkan lára àwọn Olùkọ Adjunct Lecturer ni Fordham University South Carolina and North Carolina.

Oje Olùdásílẹ̀ Carisma4U Educational Foundation, mathematics|STEM]] subjects as critical tools for improving lives and driving development.[5]

Amin Ẹyẹ

Amin ẹyẹ Sphere Woman of the Month: Adetola Salau by Princewill Ohaji July 6, 2021.[6]

Amin ẹyẹ 100 top Career women in Africa[7]

Awọn Iwe Ti Otiko

Transforming learning through relevant STEM education for Nigerian students : (Work in Progress by the Social Innovation Enterprise; Carisma4U Educational Foundation)[8]

References

Àdàkọ:Politician-stub

Àdàkọ:Draft categories