Ayoka Olufunmilayo Adebambo
Ayoka Olufunmilayo Adebambo | |
---|---|
Ọjọ́ìbí | Owerri, Nigeria |
Orílẹ̀-èdè | ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà |
Ẹ̀kọ́ | Yunifásítì ìlú Ibadan |
Iṣẹ́ | Academics |
Employer | Federal University of Agriculture Abeokuta, Nigeria |
Gbajúmọ̀ fún | First female Professor of Animal Breeding and Genetics in Nigeria |
Title | Professor |
Ayoka Olufunmilayo Adebambo jẹ́ onímọ̀ sáyẹ́ǹsì ọmọ Orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti Òjògbón nínú títún àwọn àbùdá ẹranko ṣe àti ìmò Ìṣiṣẹ́àbínimọ́.[1] Òun ni ọ̀jọ̀gbọ́n obìnrin àkọ́kọ́ nínú ìmò títún àbùdá ẹranko ṣe àti nínú ìmò ìsisẹ́àbínimọ́.[2][3] Ní oṣù kẹsàn-án ọdún 2010, ó gba àmì-ẹ̀yẹ Fellow of the Animal Science Association of Nigeria (ASAN).[4]
Isẹ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
Iṣẹ́ ọ̀jọ̀gbọ́n Ayoka bẹ̀rẹ̀ ní Yunifásítì ìlú Ìbàdàn níbi tí ó ń ti ń fi àwọn iṣẹ́ rẹ̀ kọ̀kan hàn kí ó tó lọ sí Institute of Agricultural Research and Training ní Yunifásítì Ọbáfẹ́mi Awólọ́wọ̀, Ile-Ife. Nígbà tí ó wà ní Ile-Ife, ó kó ọ̀pọ̀lọpọ̀ akitiyan nínú títún àbùdá àwọn elédè ṣe láti mú èrè wá ní títà wọn. Ní ọdún 1993, ó lọ sí ẹ̀ka ìmò títún àbùdá ẹranko ṣe ní Federal University of Agriculture, ti Abeokuta, Nàìjíríà. Ó wà lára àwọn adarí ilé-ìwé náà.[1]
Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
- ↑ 1.0 1.1 "Professor Olufunmilayo Ayoka Adebambo". AnGR NIGERIA (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2021-04-10. Retrieved 2021-04-10.
- ↑ Nigeria, Media (2018-03-19). "List Of Nigerian First Male & Female Professors In Various Disciplines". Media Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 2021-04-10. Retrieved 2021-04-10.
- ↑ EduCeleb (2017-10-04). "List of Pioneer Professors in Nigeria". EduCeleb (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-04-10.
- ↑ Àṣìṣe ìtọ́kasí: Invalid
<ref>
tag; no text was provided for refs named:1