Jump to content

Agbègbè Ìjọba Ìbílẹ̀ Abaji

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
(Àtúnjúwe láti Agbegbe Ijoba Ibile Abaji)

Abuja, olú ìlú orílẹ̀-èdè ní Nàìjíríà. Abuja tí ó jẹ́ olú ìlú ìjọba àpapọ̀, ní àwọn ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́fà àti àwọn agbègbe tí ó ju àádọ́a, tí a ṣì máa sọ̀rọ̀ nípa ọ̀kan lára àwọn ìjọba ìbílẹ̀ Abuja, tí ti orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Abaji.

[1]

Abaji jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ìjọba ìbílẹ̀ tí ó gbajúmọ̀ ní Abuja, ó sì jẹ́ ibùgbé fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ àwọn ilé-iṣẹ́ ńlá ní orílẹ̀-èdè Naijiria. Abaji, tí ó súmọ́ ìlú Lọ́kọ́ja je mímọ̀ fún àṣà Hausa, Gbayi, Ebira àti Bassa. Wọ́n dá a sílẹ̀ ní ọdún 1986 gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan nínú àwọn ìjọba ìbílẹ̀ mẹ́rin ìṣájú ní Abuja.

Àwọn Ìtọ́kasí