Akinsemoyin

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Akinsemoyin
Reign c1704 - 1749
Predecessor Gabaro
Successor Eletu Kekere
Issue
Sadeko, Amore/Olukokun, Abisako, Jolasun, Gbosebi and Aina Egbe[1]
Father Ado
Born Lagos
Died Lagos
Burial Benin

Oba Akinsemoyin jẹ́ Oba Èkó láti ọdún 1704 sí 1749. Bàbá rẹ̀ ni Oba Ado, àwọn ẹbí rẹ̀ sì ni Erelu Kuti àti Oba Gabaro, ẹni tí ó jọba ṣáájú Akinsemoyin.[2]

Gégé bí Justice J. O. Kassim ṣe fi léde ní ọjọ́ kàndínlógún oṣù kẹsàn-án ọdún 1978, ọmọ ọkùnrin mẹ́fà ni Akinsemoyin ní, orúkọ wọn ni, Sadeko, Amore/Olukokun, Abisako, Jolasun, Gbosebi àti Aina Egbe.[1]

Díè tí ó gbajúmọ̀ nínú àwọn ọmọ ọmọbìnrin Akinsemoyin ni: Onisiwo, Oniru, Oluwa, àti Akogun.[3][4][5]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. 1.0 1.1 Osuntokun, Akinjide (1987). History of the Peoples of Lagos State. Lantern Books, 1987. pp. 44. ISBN 9789782281487. 
  2. Mann, Kristin (2007). Slavery and the Birth of an African City: Lagos, 1760-1900. Indiana University Press, 2007. p. 45. ISBN 9780253348845. https://archive.org/details/slaverybirthafri00mann. 
  3. Àṣìṣe ìtọ́kasí: Invalid <ref> tag; no text was provided for refs named Cole
  4. "Chief Yesufu Abiodun Oniru". Facebook. 
  5. Rufus T. Akinyele (2009). African Cities: Competing Claims on Urban Spaces. BRILL, 2009. pp. 115–117. ISBN 9789004162648. https://books.google.com/books?id=A_IsNliDF6kC&dq=oniru+oluwa+onisiwo&pg=PA115.