Dauda Soroye Adegbenro

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Alhaji Olóyè Dauda Soroye Adegbenro (1909 - 1975) jẹ olóṣèlú ọmọ orilẹ-ede Naijiria to jẹ mínísítà fún ọrọ ilẹ pẹlu iṣẹ atí adari orilẹ-ède ti ẹgbẹ Action Group (AG).[1]

Ìpele ìbẹrẹ ti igbesi ayé rẹ[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ọdún 1909 ni wọ́n bí Adegbenro ní Ago-Owu, Abéòkúta, ìpínlẹ̀ Ògùn.[2] Dauda Soroye Adegbenro lọ sí ileewe African School, Owowo fún ètò ẹkọ alakọbẹrẹ ko to lọ sí Baptist Boys High School, Abéòkúta àti Abeokuta Grammar School fún ẹkọ gírámà.

Bí o ṣe gbà ṣiṣẹ[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rẹ̀ pẹ̀lú àjọ Nigeria Railway Corporation gẹ́gẹ́ bí akọ̀wé láti ọdún 1930 sí 1937. Lẹ́yìn ìyẹn, ó ṣiṣẹ́ olùtọ́jú ilé ìtajà pẹ̀lú United African Company.[3]

Àwọn itọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Toyin., Falola (2009). Historical dictionary of Nigeria. Genova, Ann.. Lanham, Md.: Scarecrow Press. ISBN 9780810856158. OCLC 310171807. 
  2. "D.S. Adegbenro: The Owu-born Premier of Western region". 
  3. "Adegbenro Dauda Soroye". Litcaf. 2016-01-22. Retrieved 2021-04-27.