Franklin Erepamo Osaisai

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Franklin Erepamo Osaisai (tí à bí ní oṣù Kẹwàá ọjọ́ kìíní, ọdún 1958) jẹ́ onímọ̀-ẹ̀rọ ìparun Nàìjíríà kan, onímọ̀ ìjìnlẹ̀ agbaára àti olùdarí Gbogbogbo tẹlẹ̀ àti Alákóso Aláṣẹ tí i Ìgbìmò Agbára Atomic Nigeria.[1]

Igbesi aye ati iṣẹ[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ó tí gbà ẹ̀kọ́ gírámà ní Ìpínlẹ̀ Bayelsa, níbi tí i ó tí gbà ìwé ẹ̀rí ilé -ìwé West Africa (WASC) níí oṣù kẹfà ọdún 1977. Ó lọ sí Ilé -ẹ̀kọ́ gíga tí Port Harcourt ní ibi tí ó tí gbà òye (B.sc) nií kemistri láti ilé -ìwé tí àwọn ìmọ̀-ẹrọ́ Kẹ́míkàli tí ilé -ẹkọ́ gíga ní oṣù karùn-ún ọdún 1981. Lẹyìn náà ó gbà aamí-ẹ̀kọ́ ìwé -ẹ̀kọ́ ìwé-ẹ̀kọ́ gíga, tí o fún un ní òye títún tòsí àti oyè P.hD ni ìmọ̀-ẹrọ iparun (1984-1987) láti University of California.[2] O bẹrẹ̀ iṣẹ́ rẹ̀ ní Ilé-ẹ̀kọ́ gíga tí California gẹgẹ́ bí olùkọ́ ni ṣáájú kí o darapọ̀ mọ iṣẹ́ ti Yunifásítì ìlú Port Harcourt níbi tí o ṣé amọja ní ìmọ̀-ẹrọ́ Reactor Nuclear. [3] Lẹ́yìn náà o dì Olùdarí gbogbogbo àti alákóso aláṣẹ tí Nigeria Atomic Energy Commission (NAEC) labẹ ìṣàkóso tí Olóyè Olusegun Obasanjo, tó jẹ́ Ààrẹ àná tí Federal Republic of Nigeria. [4] O ti ṣiṣẹ́ ní ọpọlọpọ àwọn àjọ alámọ̀dajú. [5]

Àwọn ẹlẹ́gbẹ́ àti ẹgbẹ́[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Ẹlẹ́gbẹ́ tí Ilé -ẹ̀kọ́ gíga tí Imọ -ẹrọ Nàìjíríà
  • Àkójọ ti University of Port Harcourt eènìyàn

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]