Ireti Osayemi

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Ireti Osayemi
Ireti Osayemi
Ọjọ́ìbíIreti Osayemi
Oṣù Kínní 14, 1982 (1982-01-14) (ọmọ ọdún 42)
Lagos State
Orílẹ̀-èdèNigerian
Iṣẹ́Actress, producer, performer

Ireti Osayemi jẹ ògbóǹtarìgì òṣèrébìnrin sinimá àgbéléwò ti orílẹ̀-èdè Naijiria. Ó sì máa ń se fíìmù ní èdè Yorùbá àti Gẹ̀ẹ́sì.[1]

Ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé àti ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ọjọ́ kẹrìnlá, oṣù kìíní, ọdún 1982 ni a bí Osayemi sí apá Gúúsù ti apá ìwọ̀-oòrùn ilẹ̀ Naijiria. Ipinle Eko, ní Lagos state primary school ni ó ti bẹ̀rẹ̀ ètò èkọ́ rẹ̀ tí ó sì parí. Ó gboyè nínú ẹ̀kọ́ Economics ní Lagos State University. Ó ti siṣẹ́ lórí ọ̀pọ̀lọpọ̀ eré bíi; heavy storm, Ife owo, Spiritual war, Towo tomo, Oreke mulero àti béè bẹ́è lọ.[2][3]

Àtòjọ àwọn àmì-ẹ̀yẹ tó ti gbà[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Year Award ceremony Category Film Result Ref
2017 Best of Nollywood Awards Best Supporting Actress –Yoruba Ojo Meta Gbàá [4]
2020 Best of Nollywood Awards Best Supporting Actress –Yoruba style="background: #FDD; color: black; vertical-align: middle; text-align: center; " class="no table-no2"|Wọ́n pèé [5]

Àwọn ìtọ́tasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "My kids are my fashion police –Ireti Osayemi". Punch Newspapers. 2015-12-15. Retrieved 2019-09-21. 
  2. Choudhary, Vijendra (2021-01-11). "Ireti Osayemi Biography, Wiki- Age, Husband, Net Worth, Instagram". Areal News. Archived from the original on 2021-11-08. Retrieved 2022-05-20. 
  3. Ayotunde, Praise Abolaji (2021-12-29). "Ireti Osayemi Biography - Age, Career, Family, Education and Net Worth". Amebo Online. Retrieved 2022-05-20. 
  4. "BON Awards 2017: Kannywood’s Ali Nuhu receives Special Recognition Award". Daily Trust (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2017-11-23. Retrieved 2021-10-07. 
  5. Augoye, Jayne (2020-12-02). "2020 BON: Here are 5 nominees for ‘Best Kiss’ category" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-10-11.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)