Marcus Garvey

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Lọ sí: atọ́ka, àwárí
Marcus Garvey

Garvey in 1924
Ìbí Marcus Mosiah Garvey, Jr.
17 Oṣù Kẹjọ, 1887(1887-08-17)
St. Ann's Bay, Jamaica
Aláìsí 10 Oṣù Kẹfà, 1940 (ọmọ ọdún 52)
London, England, UK
Iṣẹ́ Publisher, journalist
Known for Activism, Black Nationalism, Pan-Africanism
Àwọn ọmọ Marcus Mosiah Garvey, III (born 17 September 1930) and Julius
Àwọn òbí Marcus Mosiah Garvey, Sr.
Sarah Jane Richards


Marcus Mosiah Garvey, Jr., ONH (17 August 1887 – 10 June 1940)[1] je atewejade, oniroyin, onisowo, ati olohun ara Jamaika to da aba irinkankan Iseolomoorile-ede Adulawo ati Ise Gbogbo Afrika, nitoe to fi da Egbe Igbesoke Adulawo Agbalaaye ati Egbe awon Agbajo Afrika (UNIA-ACL).[2] O seidasile ile-ise Black Star Line, bi apa eto Ipada si Afrika, to poloungo ipada lo si Afrika gbogbo awon Omo Afrika Leyin-odi.


[àtúnṣe] Itokasi

  1. Encyclopedia Britannica Online Marcus Garvey profile. Retrieved 20 February 2008.
  2. "The "Back to Africa" Myth". UNIA-ACL website. 14 July 2005. Archived from the original on 30 December 2006. http://web.archive.org/web/20061230195707/http://www.unia-acl.org/archive/themyth.htm. Retrieved 2007-04-01. 
Àwọn irinṣẹ́ àdáni
Àwọn orúkọàyè

Àwọn oriṣiríṣi
Àwọn ìwò
Àwọn ìgbéṣe
Atọ́ka
Ìkópa
Àpótí irinṣẹ
Àwọn èdè míràn