Moji Olaiya

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Moji Olaiya
Ọjọ́ìbí(1975-02-27)Oṣù Kejì 27, 1975
AláìsíMay 17, 2017(2017-05-17) (ọmọ ọdún 42)
Canada
Iṣẹ́eléré orí-ìtàǵe

Mojí Ọláìyá (bíi ní Ọjọ́ kẹtàdínlọ̀gbọ̀n Oṣù kejì ọdùn 1975 – ọjọ́kẹtàdínlogún Oṣù Kàrún-ún ọdún 2017) jẹ́ eléré orí-ìtàǵe Yorùbá ọmọ orílẹ̀-èdè Naijiria.[1]

Iṣẹ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Mojí jẹ́ ọmọ Victor Olaiya gbajú-gbajà ọ̀kọrin highlife ilé Nàìjíríà. Mojí Õláìyá bẹ̀rẹ̀ eré orí-ìtàgé rẹ̀ pẹlú ilé iṣẹ́ Wale Adenuga Super Story.[2] Ó kopa to laami laaka ninu awon osere Nollywood Yoruba ati Geesi lapapo.[3] Mojí di gbajúgbajà òṣèré sinimá àgbéléwò láàrin àwọn akẹgbẹ́ rẹ̀ tó kù látàrí ipa rẹ̀ tó kó nínú eré Gẹ̀ẹ́sì tí a mọ̀ sí No Pains No Gains, ní èyí ti ó tí kópa gẹ́gẹ́ bí Ìrètí, Sade Blade (2005), Nkan adun (2008) ati Omo iya meta leyi (2009). Bakan naa lo tun han ninu Agunbaniro. ni odun 2003. Won tun yaan fun ami eye idani-lola ti (The Reel Award Best Supporting Actress of the Year), bakan naa lo tun jawe olubori ninu idije ami eye 'Oserebinrin to dara julo' (Best New Actress Award) ni osu kejo odun 2016.[4]


ni odun 2016, Moji se fiimu ara kan jade,ti o pe ni, Iya Okomi,[5] to safiha awon osere akegbe re to ku bii: Foluke Daramola àti Funsho Adeolu, ni eyi ti won safihan re akoko ni gbongan ni Ilu-Eko ni osu keje.[6]

Igbesi Aye re[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Moji Olaiya se igbeyawo pelu Bayo Okesola ni odun 2007, ko pe ko jina won korawon sile.[7][8][9] Moji yi pada lati esin Kiristeni si esin Islam ni odun 2014 funra re.[10][11]

O ku ni ojo-ketadinlogun osu karun-un odun 2017, latari aisan Okan ni Ilu Canada, leyin osu meji ti o bimo keji.[12] ki olorun o bawa fOrun ke. O digba O di gbere.

Awon Ere ti O ti Kopa[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Aje nile Olokun
  • Ojiji Aye
  • Apaadi
  • Omo Iya Meta leyi (2009)
  • Nkan adun (2008)
  • Sade Blade (2005)

Awon Itoni[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Esho, Wemi (2015-03-03). "Photos from her 40th birthday bash". Pulse Nigeria. Retrieved 2022-03-19. 
  2. "I was the breadwinner while my marriage lasted — Actress, Moji Olaiya". Nigerian Tribune. http://www.tribune.com.ng/news2013/index.php/en/component/k2/item/8979-i-was-the-breadwinner-while-my-marriage-lasted-actress-moji-olaiya. Retrieved 26 March 2015. 
  3. NONYE BEN-NWANKWO. "Fathia Balogun had nothing to do with my broken marriage – Moji Olaiya". The Punch. Archived from the original on 2015-06-03. https://web.archive.org/web/20150603184100/http://www.punchng.com/feature/moji-olaiya-on-her-broken-marriage-fathia-balogun-has-nothing-to-do-with-it/. 
  4. "Moji Olaiya Latest News". Legit.ng - Nigeria news. 2022-03-19. Archived from the original on 2022-03-19. Retrieved 2022-03-19. 
  5. "Moji Olaiya’s movie “Iya Okomi” to premiere in July". Nigerian Pilot. 31 July 2016. Retrieved 15 September 2016. 
  6. Abumere, Princess (2016-06-03). "Moji Olaiya’s movie to premiere in July". Pulse Nigeria. Retrieved 2022-03-19. 
  7. "Violence forced me out of Marriage". Modern Ghana. 31 January 2014. Retrieved 26 March 2015. 
  8. Mary Jane Eze. "I WISH I HAVE A MAN BESIDES ME @40- MOJI OLAIYA LAMENTS". Nigeria Films. 
  9. "Moji Olaiya left her husband because of domestic Violence". http://www.nollywoodmagazine.com/2015/01/moji-olaiya-actress-left-her-husband-because-of-domestic-violence.html. Retrieved 26 March 2015. 
  10. Omoruyi, Omoleye; Aminu, Ado (2015-03-03). "Fabulous at 40! Fathia Balogun, Yomi Fash, Ronke Oshodi, Eniola Badmus, others party with Nollywood actress, Moji Olaiya (PHOTOS) » YNaija". YNaija. Retrieved 2022-03-19. 
  11. "Nollywood Yoruba Movie Actress Moji Olaiya Cries ‘I don’t have any Alhaji lover’". Daily Mail. 3 November 2014. Archived from the original on 2 April 2015. https://web.archive.org/web/20150402181812/http://dailymail.com.ng/nollywood-yoruba-movie-actress-moji-olaiya-cries-i-dont-have-any-alhaji-lover/. Retrieved 16 March 2015. 
  12. Augoye, Jayne (2017-05-18). "Veteran Yoruba movie actress, Moji Olaiya, is dead". Premium Times Nigeria. Retrieved 2022-03-19.