Sophie Ndaba

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Sophie Lichaba
Ọjọ́ìbíSophie Mphasane
Oṣù Kẹta 8, 1973 (1973-03-08) (ọmọ ọdún 51)
Soweto, South Africa
Orúkọ mírànSophie Ndaba
Iṣẹ́
  • Actor
  • model
  • event organiser
Ìgbà iṣẹ́1992 – present
Olólùfẹ́
Alábàálòpọ̀Keith Harrington (2011–2013)
Àwọn ọmọ
  • Rudo Ndaba
  • Lwandle Ndaba

Sophie Lichaba (bíi ni ọjọ́ kọkàndínlógbọ̀n oṣù kẹfà ọdún 1973)[1], jẹ́ òṣèré ni orílẹ̀ èdè South Áfríkà.

Ẹ̀kọ́[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ó lọ sí ilé ẹ̀kọ́ ni Zimbabwe[2], ìyá rẹ gbé lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn aláìní ìyá kí ó ba le ni ẹ̀kọ́ gidi.[3] Bàbá rẹ̀ kú ní ọdún 2016.[4] [5]Ó bí ọmọ méjì fún ọkọ rẹ tẹ́lẹ̀, Themba Ndaba[6]. Ní ọdún 2018, àwọn kan gbé aruyewuye jáde pé Lichaba tí kú.[7]


Àṣàyàn àwọn eré rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Class of '92
  • Egoli: Place of Gold
  • Generations[8]
  • Gog' Helen
  • Yizo Yizo
  • Soul City
  • She is King
  • Isidingo
  • High Rollers - Season 2
  • Lockdown

Àwọn amì-ẹ̀yẹ ìdánilọ́lá rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Duku Duku Award for “Best Soap Actress” in 2003[9]
  • Golden Horn Award for “Best Comic Actor” in 2009[9]
  • Woman Of Inspiration Award[10]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Sophie Ndaba Biography: Weight loss, Illness, Age, Husband, Children". ZAlebs. Africa New Media Group. 13 September 2013. Archived from the original on 2019-10-26. Retrieved 2020-03-23. 
  2. Memoir. [1] Archived 2019-10-26 at the Wayback Machine., Sophie Ndaba Biography. Retrieved on 26 October 2019
  3. Chidavaenzi, Phillip (September 2015). "Fashion keeps me young – Sophie Ndaba". Newsday. Retrieved 2020-03-23. 
  4. "Sophie Ndaba still believes in love". Entertainment SA. 2017. Retrieved 2020-03-23. 
  5. "Sophie Ndaba reflects on losing her dad six weeks ago". SowetanLIVE. Arena Holdings. 4 November 2016. Retrieved 2020-03-23. 
  6. Winters, Hope (2017-12-11). "Sophie Ndaba secretly weds third husband in Italy". All4Women. https://www.all4women.co.za/1325083/entertainment/sa-celebs/sophie-ndaba-secretly-ties-knot. 
  7. https://www.iol.co.za/entertainment/celebrity-news/local/sophie-lichaba-opens-up-about-going-to-the-emergency-room-during-covid-19-48809245
  8. The South African TV authority. [2], Sophie Ndaba, 2014. Retrieved on 3 October 2014.
  9. 9.0 9.1 "Sophie Ndaba Biography: Weight loss, Illness, Age, Husband, Children". ZAlebs. Africa New Media Group. 13 September 2013. Archived from the original on 2019-10-26. Retrieved 2020-03-23. 
  10. "Sophie Ndaba", Women of inspiration, Cape Town, 2010. Retrieved on 3 October 2014.