Taiwo Olowo

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Taiwo Olowo
Ọjọ́ìbíDaniel Conrad Taiwo "Olowo"
1781
Isheri, Lagos
Aláìsí20 February 1901(1901-02-20) (ọmọ ọdún 119–120)
Lagos, Lagos Colony
Parent(s)
  • Chief Oluwole (father)

Olóyè Daniel Conrad Taiwo (tí a bí ní ọdún 1781 tí ó sì fi ayé sílẹ̀ ní ọjọ́ ogún oṣù kejì ọdún 1901), àwọn ènìyàn tún mọ̀ọ́ sí Taiwo Olówó[1]. Ó jẹ́ olùtà ohun ìjà ogun, olówó àwọn ẹrú, afifúni àti olórí àdúgbò kan nígbà tí Èkó wà lábé ìjọba Britain.

Ìpìlẹ̀ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

A bí Taiwo Olowo ní ọdún 1781 ní Isheri, àdúgbò kan ní ìpínlẹ̀ Eko.[2] Baba rẹ̀, Oluwole, jẹ́ Olofin ìlú rẹ̀, ó sì fi ayé sílẹ̀ ní ọdún 1809.[3] Olowo kó lọ sí ìlú Èkó ní ọdún 1848 ó sì jẹ́ ẹrú Ogunmade fún ìgbà díẹ̀.[4]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Olukoju, Akyeampong, Bates, Nunn, & Robertson (11 August 2014). Accumulation and Conspicuous Consumption: The Poverty of Entrepreneurship in Western Nigeria, ca. 1850–1930 in Africa's Development in Historical Perspective. Cambridge University Press, Aug 11, 2014. pp. 210–211. ISBN 9781139992695. 
  2. "Daniel Conrad Taiwo: 18th century Lagos Island business icon". National Mirror. Archived from the original on December 20, 2016. Retrieved 10 December 2016.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  3. "Taiwo Conrad Olowo – Litcaf". 17 January 2016. 
  4. Cole, Patrick (17 April 1975). Modern and Traditional Elites in the Politics of Lagos. Cambridge University Press, 1975. pp. 30–31. ISBN 9780521204392. https://archive.org/details/moderntraditiona0000cole/page/30.