Yunifásítì ìlú Èkó

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
University of Lagos students festival 15
Yunifásítì ìlú Èkó
University of Lagos
MottoIn deed and in truth.
Established1962
TypePublic
PresidentProf Tolu Olukayode Odugbemi
LocationNàìjíríàLagos, Nigeria
CampusUrban
Websitewww.unilag.edu.ng
Faculty of Science

Yunifásítì ìlú Èkó (University of Lagos tàbí UNILAG) jé fásitì ìjọba àpapò ni Naijiria tó bùdó si ilu Èkó.


Ìtàn yunifásítì ìlú Èkó[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

A dá UNILAG silẹ ni ọdún 1962, ọdún méjì lẹ́yìn òmìnira Naijiria independence of Nigeria láti ọwó àwọn Britain. Ó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn yunifásítì márùn-ún tí a dá lè ní orílè-èdè Nàìjíríà, tí a mò sí "first generation universities".[1][2] Eni Njoku ni a yàn gẹ́gẹ́ bí alákòóso àkọ́kọ́ ní yunifásítì ní ọdún 1962, èyí tí ọ́ ṣe títí di ọdún 1965 tí a sì ni ipò pada pẹ̀lú Saburi Biobaku. síbẹ̀síbẹ̀, nítorí àwọn àríyànjiyàn nípa bí a sè yàn sí ipò , ọ̀gbẹ́ni Kayode Adams gún Saburi pa , akẹ́kọ̀ọ́ tí ó gbàgbọ́ pé ááyan Saburi nítorí ẹyà ti ọ sí bójú mu.[3]

Láti ọdún 2017 [4] Títí di ojo òní , igbakeji olórí ni ọ̀jọ̀gbọ́n Oluwatoyin Ogundipe.ni ọdún 2019, Telifísàn BBC sọ̀rọ̀ nípa "female reporters were sexually harassed, propositioned and put under pressure by senior lecturers at the institutions – all the while wearing secret cameras".[5][6] yíyọ àwọn obìrin oníròyìn lẹ́nu lórí ìbálópọ̀ àti ìfúgunmọ́ láti ọwọ́ àwọn olùkọ́ àgbà ní yunifásítì ní àwọn ilé-ìwé - láti ìgbà yìí wa ni wọ́n gbé kámẹ́rà pamọ́ sára.

Yunifásítì tí gbé oríṣiríṣi ọ̀jọ̀gbọ́n tí ó yanrantí jáde nínú ìmọ̀ síyẹ́ǹsì, òṣèlú, amòfin, àwọn oníṣòwò ńlá , òǹkọ̀wé, àwọn eléré ìdárayá, àwọn ọba, ìmọ̀-ẹ̀rọ,ti ìlú Nàìjíríà àwọn olóye gbogbo , àti àwọn akẹ́kọ̀ọ́ ilé ìwe mìíràn pẹ̀lú . Ni oṣù kẹsàn-án ọdún 2020, ọ̀kan lára àwọn nobel laureate àti ọ̀kan lára Pulitzer prize laureate ni wọ́n kà gẹ́gẹ́ bí i ọmọ ilẹ́ ìwé yunifásítì ìlú Èkó , ọmọ ilẹ́ ìwé, olùkọ́, tàbí òṣìṣẹ́.

Faculty of Science, University of Lagos
University of Lagos Lagoon front view from Seaside cottage theatre, Bariga
Lagoon Front Silhouette
View of the Third Mainland Bridge From the Lagoon Front
Green Space in University of Lagos


Ìran[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Láti jẹ ile ẹkọ tó Dára jù lọ nínú títà yo imo, ìwà ati rí ran àwon eniyan lowo.[7]

Iṣẹ[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Láti ṣe ibùgbé tí ó dára fún ẹ̀kó, ìwé kika, Ìwádìí àti ìdàgbàsókè, níbití òṣìṣẹ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ yóò ní Àjosepò tó dán mọ́rán láti kojú ẹlẹ́gbẹ́ won ni gbogbo àgbáyé [8]

Faculty of Science, University of Lagos
University of Lagos Lagoon front view from Seaside cottage theatre, Bariga
Lagoon Front Silhouette
View of the Third Mainland Bridge From the Lagoon Front
Green Space in University of Lagos

Ile kíkọ ati Arabara[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]


  1. "Nigerian Education Profile". United States Diplomatic Mission to Nigeria. Archived from the original on 17 March 2010. Retrieved 15 October 2013.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  2. "University of Lagos (1962- ) •". 10 December 2011. 
  3. "Saburi Biobaku: Unilag's VC who was stabbed by a student who disagreed with his choice as VC". 4 February 2018. 
  4. "Ambode Congratulates New UNILAG VC, Prof Oluwatoyin Ogundipe". 30 October 2017. Archived from the original on 4 June 2020. Retrieved 25 February 2022. 
  5. "'Sex for grades': Undercover in West African universities" (in en). BBC News. 7 October 2019. https://www.bbc.com/news/av/world-africa-49907376/sex-for-grades-undercover-in-west-african-universities. 
  6. "That BBC's sting operation in UNILAG". 15 October 2019. 
  7. "About Us". University of Lagos (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 28 February 2022. 
  8. Àṣìṣe ìtọ́kasí: Invalid <ref> tag; no text was provided for refs named :0