Alaba Lawson

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
(Àtúnjúwe láti Àlàbá Lawson)
Alaba Lawson
Ọjọ́ìbíOṣù Kínní 18, 1951 (1951-01-18) (ọmọ ọdún 73)
Abeokuta, Ogun State, Nigeria
Orílẹ̀-èdèNigerian
Orúkọ mírànIyalode Alaba Lawson
Iléẹ̀kọ́ gíga
  • Abeokuta Girls Grammar School
  • St. Nicholas Montessori Teachers’ Training College
Iṣẹ́
Ìgbà iṣẹ́1977–present
EmployerNACCIMA
Board member ofChairman, Board of Governing Council, Moshood Abiola Polytechnic, Ogun State
Websitealabalawson.org

Olóyè Alaba Lawson (tí a bí ní Omidan Alaba Oluwaseun Lawson ni ọjọ kejì-dín-lógún oṣú kínní ọdún 1951) jẹ ọmọ orilẹ-èdè Naijiria; olokoowo nla, oniṣowo agba ati ọmọwe sì ni pẹlu. Òun ni ó jẹ́ obinrin àkọ́kọ́ tí ó jẹ aarẹ ẹgbẹ NACCIMA ati Alága Ìgbìmọ̀ awọn Alakoso ti ile ẹko gbogboniṣe, Moshood Abiola ni Ìpínlẹ̀ Ogun ni orilẹ-ede Naijiria.

Olóyè Lawson ti di ipo aarẹ agbarijọpọ awọn lọbalọba to jẹ́ obinrin ni orilẹ-ede Naijiria (Forum of Female Traditional Rulers in Nigeria).

Ìbẹ̀rẹ̀ igbe ayé àti ètò ẹkọ[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

A bi Alaba si inu ẹbi Jibolu-Taiwo ti ìlú Abeokuta, ti i ṣe olu ilu fun ipinlẹ Ogun, níbi ti o ti pari ile-ẹkọ alakọbẹrẹ ati girama ni ile-ẹkọ St. James’ African Primary School, Idi-Ape, Abeokuta laarin ọdun 1957 ati 1962 fun ẹkọ alakọbẹrẹ ati Ile-ẹkọ girama fun awọn obinrin (Abeokuta Girls Grammar School), Abeokuta, eleyi ti o pari ni ọdun 1968[1] ki o to tẹsiwaju lati lọ si ile ẹkọ fun awọn olukọni ni St. Nicholas Montessori Teachers’ Training College ti o wa ni Prince's Gate, England ni ọdun 1973 ni bi ti o ti peregede ti o si gba iwe ẹri diploma ninu ikọni (Diploma in Education)[2].

Awọn Itọkasi[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. https://www.vanguardngr.com/2017/05/naccima-gets-first-female-national-president/
  2. "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2020-02-19. Retrieved 2022-05-20.