Òjògbón Abdulrasheed Na'Allah

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Òjògbón Abdulrasheed Na'allah tí a bi ní ìlú Ilorin, ìpínlè kwara, Nàìjíríà[1], a bi ní ojó kokanlelogun, osu kejila(December 21), odun 1962 [1]. Òjògbón Abdulrasheed ni olori yunifásitì ìpínlè Kwara lati odun 2009 dé odun 2019(odún mewa), ósì di olori Yunifásitì ti ìlú Àbújá ní odun 2019 [2], ipò tí o dimú di òní. Ojogbon Abdulrasheed keko gboye nínú ìmò Art(Bachelor of Art) ní yunifásitì Ìlorin ní odun 1988, o si tún tè siwaju ní ìmò literature in English(Master of art) ní yunifásitì kanáà ní odun 1992 [3]., Òjògbón Abdulrasheed ti ko ìwé tí ópò, apere ìwé tí o ko ni; Seriya, Omolekewu àti Ilorin ò [4]

Àwon Ìtókasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. 1.0 1.1 "Prabook". prabook.com. Retrieved 2022-03-02. 
  2. Olufemi, Alfred (2021-03-14). "EXCLUSIVE: UNIABUJA VC left KWASU with 'huge' retirement package despite school's indebtedness". Premium Times Nigeria. Retrieved 2022-03-02. 
  3. "Prof Na’allah takes over as UniAbuja VC". Daily Trust. 2019-07-02. Retrieved 2022-03-02. 
  4. Omolaoye, Sodiq (2021-07-04). "With Seriya, Omokewu, Na’Allah deepens Islamic study". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News. Retrieved 2022-03-02.