Akanlo-ede
Ìrísí
Hw far
Ìwúlò rẹ̀
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]Àkànlò-èdè wúlò púpọ̀ fún elédè Yorùbá l'ọ́pọ̀lọpọ̀ nígbà tí wọ́n bá fẹ́ pẹ́ ọ̀rọ̀ kan sọ. Àpẹẹrẹ:
- Júbà ehoro : KÍ ènìyàn sálọ
- Gbèkurujẹ l'ọ́wọ́ ẹbọra : KÍ ènìyàn kú
- Ṣe àyà gbàngbà : Kí ènìyàn ní ìgboyà
- Fárígá : Kí ènìyàn kọ̀ jálẹ̀
- Fi àáké kọ́rí Èyí náà túmọ̀ sí kí ènìyàn kọ̀ jálẹ̀
- F'apá jánú : KÍ ènìyàn máa sọ̀rọ̀ lórí ohun tí kò tó nǹkan
- Jẹ orí ahun [1] : Kí ènìyàn dájú
- Àkàrà tú sepo : Àṣírí tú
- ṣe ọwọ́ kúdúrú : Kí ènìyàn gba owó ẹ̀yìn
- Jẹ iyán ni ìṣù : Kí ènìyàn tẹ́
- kọ ẹ̀yin ẹni sómi : Kí wọ́n dájú ènìyàn
Àwọn ìtọ́kasí
[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]- ↑ "Akomolede BBC Yoruba: Ìtúmọ̀ Àkànlò èdè àti ìwúlò rẹ̀ lóde òní". BBC News Yorùbá. 2021-04-06. Retrieved 2024-01-21.