Jump to content

Aláàfin Gberu

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Gberu fìgbà kan jẹ́ Aláàfin ti ìlú Ọ̀yọ́. Ó wà lórí oyè láti ọdún 1730 wọ ọdún 1746.[1]Gberu ni ọ̀rẹ́ tímọ́tímọ́ kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Jambu, tó fi jẹ Baṣọ̀run (èyí tí ń ṣe olórí àwọn Ọ̀yọ́ Mèsì, àti olùdámọ̀ràn ìlú), àmọ́ wọ́n kẹ̀yìn si, nígbà tí àwọn méjèèejì bẹ̀rẹ̀ sí ní dìtẹ̀ mọ́ ara wọn.[2]

Lẹ́yìn tí wọ́n kọ̀ ọ́ bí ọba, Gberu pa ara rẹ̀.[3]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Alaafin of Oyo: Wo Alàáfin 43 tó jẹ́ láti ìgbà ìwásẹ̀ ṣáajú Lamide Adeyemi tó ṣẹ̀ṣẹ̀ wàjà". BBC News Yorùbá. 2022-04-24. Retrieved 2024-06-17. 
  2. Johnson, Samuel (August 2011). The history of the Yorubas : from the earliest times to the beginning of the British Protectorate. ISBN 0948390891. OCLC 989713421. 
  3. Law, R. C. C. (1971). "The constitutional troubles of Ọyọ in the eighteenth century". The Journal of African History 12 (1): 25–44. doi:10.1017/s0021853700000050. ISSN 0021-8537.