Jump to content

Bọ̀dé Ṣówandé

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Bọ̀dé Ṣówandé ni a bí ní ọjọ́Kejì oṣù Karùún, ọdún 1948 (2-05-1948), jẹ́ Ònkọ̀wé, Eléré oníṣe àti ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[1]

Iṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí Ònkọ̀wé

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ó jẹ́ olùkọ iwe nípa ọmọnìyàn àti ìṣesí àwùjọ. Ó jẹ́ ònkọ̀wé tí ó ma ń lo àwọn ọgbọ́n àtinúdá tí a ṣe lọ́jọ̀ pẹ̀lú àṣà àti ìṣe ilẹ̀ Yorùbá.[2] Ṣówandé wà lára ọ̀wọ́ ìpele ìran àwọn ònkọ̀wé Kejì nílẹ̀ Nàìjíríà, tí wọ́n ma ń kẹ́fin sí ètò ìṣèlú, bí a ṣe lè dara pọ̀ àti lòó fún ìgbéga ìṣẹ̀mí ìlú àti ènìyàn gbogbo nínú àpilẹ̀kọ wọn gbogbo.[3] Lára àwọn ikọ̀ rẹ̀ ni: Zulu Ṣófọlá, Fẹ́mi Osofisan àti Festus Iyayi.[4]Bọ̀dé Ṣówandé fi ìtàkùn website rẹ̀ tíó pè ní Tarot lọ́ọ́lẹ̀ ní Ọjàọ́ Karùún ọdún 2010. Tarot With Prayers òun lò sì tún ni Òun lò ni "Odu Themes", àti "Bọ̀dé Ṣówandé Theatre Academy", tí ó jẹ́ àyè ìkọ́ni fún àwọn òṣèré.[5]

Ó fẹ́yàwó, ó sì bímọ.

Àwọn Ìtọ́kasí

[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]
  1. Revolvy, LLC (1948-05-02). ""Bode Sowande" on Revolvy.com". Revolvy. Retrieved 2019-12-29.
  2. Admin (2017-11-23). "Prof Sowande, Omobude To Be Hosted By ANA Oyo On Saturday". PM Parrot. Retrieved 2019-12-29.
  3. Osita Okagbue, African Writers Vol. 2 1997
  4. Abolo, Greg (2018-05-10). "Performing Artists Gather At Ibadan Varsity For Bode Sowande At 70 – The Oasis Reporters". The Oasis Reporters – News on time, everytime. Retrieved 2019-12-29.
  5. "Bode Sowande Archives - Nigeria and World News". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News. Archived from the original on 2019-12-29. Retrieved 2019-12-29.