Betty Abah

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Betty Abah
Abah in 2015
Ọjọ́ìbíOṣù Kẹta 6, 1974 (1974-03-06) (ọmọ ọdún 50)
Otukpo, Benue State, Nigeria
Orílẹ̀-èdèNigerian
Iṣẹ́
  • oníróyìn
  • akọ̀wé
  • ajíjágbara fún àwọn ọmọdé àti àwọn obìnrin

Betty Abah (bíi ni ọjọ́ kẹfà oṣù kẹta ọdún 1974) jẹ́ oníróyìn, akọ̀wé àti ajíjágbara fún àwọn ọmọdé àti àwọn obìnrin. Òun ni olùdásílẹ̀ àti adarí fún CEE HOPE ní ìlú Èkó.

Ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé àti ètò-ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Betty sí ìlú Otukpo ní ìpínlẹ̀ Benue. Ó gboyè nínú ẹ̀kọ́ ìmọ̀ èdè gẹ̀ẹ́sì láti ilé ẹ̀kọ́ gíga tí University of Calabar, ó sì tẹ̀síwájú nínú ẹ̀kọ́ náà ni University of Lagos.

Iṣẹ́[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ pẹ̀lú ilé iṣẹ́ tí ó ń ṣe ìwé ìròyìn tí The Voice Newspaper ni ìpínlẹ̀ Benue. Ó ti ṣiṣé pẹlú àwọn ìwé ìròyìn bíi Newswatch, Tell Magazine àti Rocky Mountain news.[1] Ó ti kọ àwọn ìwé bíi Sound of Broken Chains, Go Tell Our King àti Mother of Multitude.[2][3] Ó dá ẹgbẹ́ CEE-HOPE kalẹ̀ ni oṣù kejìlá ọdún 2013.[4][5][6]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Nigerian Women Bear the Curse of Oil". Archived from the original on 2016-08-17. Retrieved 2020-05-25. 
  2. "JOURNALIST, BETTY ABAH BRINGS MULTIMEDIA TO POETRY". 
  3. "A word is enough for the wise! Interview with Betty Abah, Environmental Rights Action - Enanga". Archived from the original on 2017-10-19. Retrieved 2020-05-25. 
  4. Dame Awards. "The Child Friendly Reporting". Archived from the original on 19 August 2016. Retrieved 19 July 2016. 
  5. Voice of America. "Three Africans Chosen for U.S. Press Fellowships". Retrieved 19 July 2016. 
  6. Tobore Ovuoire. "PREMIUM TIMES reporters honoured at Wole Soyinka Journalism Awards". Premium Times. Retrieved 19 July 2016.