Kingsley Okonkwo

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Kingsley Okonkwo (tí wọ́n bí ní ọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n oṣù kìíní ọdún 1976) jẹ́ olùṣọ́-àgùntàn, olùdámọ̀ràn àti òǹkọ̀wé ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Òun ni olùdásílẹ̀ àti olùṣọ́-àgùntàn ti ìjọ David's Christian Centre.[1] Ó sì tún jẹ́ olùṣèdásílẹ̀ ìpérò tó jẹ́ mọ́ ọ̀rọ̀ ìfẹ́, ìbáṣepọ̀ àti ìgbéyàwó, èyí tó máa ń wáyé ní oṣooṣù.[2][3]

Àwọn ìtókasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Nigeria, Guardian (5 November 2022). "Family is the foundation of every society — Okonkwo". The Guardian Nigeria News - Nigeria and World News. Retrieved 30 September 2023. 
  2. "‘Love, Dating and Marriage’ host The 2023 Manual Conference on the need for Emotional Stability in a Relationship". BellaNaija. 2 February 2023. Retrieved 30 September 2023. 
  3. Nation, The. "Pre-marital s3xual experience waste of time – Pastor Kingsley Okonkwo". The Nation. Retrieved 30 September 2023.