Mazi Nwonwu

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Mazi Nwonwu
Ọjọ́ ìbíChiagozie Fred Nwonwu
Nkwe, Enugu, Nigeria
Pen nameMazi Nwonwu
Iṣẹ́Writer, Journalist
ÈdèEnglish, Igbo
Ọmọ orílẹ̀-èdèNigerian
CitizenshipNigeria
Ẹ̀kọ́Ilé-ẹ̀kọ́ ìkọ́ni ti ìjọba, ní ìpínlẹ̀ Kaduna
Alma materNnamdi Azikiwe University
GenresScience fiction, fantasy

Chiagozie Fred Nwonwu ẹni tí ó kọ̀wé lábẹ́ gègé orúkọ Mazi Nwonwu jẹ́ òǹkọ̀wé ti orílẹ̀-èdè Nàìjíríà, alábòójútó àti ayẹ̀ròyìn wò. Ó pẹ̀lú àwọn olùdásílẹ̀ àti alákòóso ayẹ̀ròyìn wò ti Omenana Magazine.[1][2][3][4] Ní ọdún 2017, wọ́n to orúkọ rẹ̀ wà lára ọ̀kan àwọn ènìyàn alágbára jàǹkàn-jàǹkàn ní agbègbè ìròyìn kíkọ pẹ̀lúpẹ̀lú Stephanie Busari and Fisayo Soyombo látọwọ́ YNaija.[5][6]

  1. "Mazi Nwonwu". Omenana Magazine. Retrieved August 26, 2021. 
  2. "BBC Radio 4 - Writing a New Nigeria - Meet the authors". BBC. Retrieved August 26, 2021. 
  3. Geoff, Ryman (May 31, 2018). "Mazi Chiagozie Nwonwu". Strange Horizons. Issue: 100 African Writers of SFF-Part Nine: The Ake Festival. Retrieved August 26, 2021. 
  4. "POET OF NO COUNTRY (by Eriata Oribhabor Poetry Prize Judge Mazi Chiagozie F Nwonwu)". WRR. December 20, 2012. Retrieved August 26, 2021. 
  5. YNaija (January 3, 2018). "#YNaijaPowerList2017: Stephanie Busari, Uche Pedro, Fisayo Soyombo… See the most powerful young persons in the media space » YNaija". YNaija. Retrieved August 26, 2021. 
  6. "Stephanie Busari, Morayo Afolabi-Brown, Kemi Adetiba named in #YNaijaPowerlist2017 for "Most Powerful Young People in Media"". OloriSuperGal. September 8, 2017. Retrieved August 26, 2021.