Nthati Moshesh

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Nthati Moshesh
Moshesh in 2018
Ọjọ́ìbíOṣù Kẹjọ 28, 1969 (1969-08-28) (ọmọ ọdún 54)
Orílẹ̀-èdèSouth Africa
Ẹ̀kọ́St. Andrew's School for Girls
Technikon Natal
Iṣẹ́Actress
Gbajúmọ̀ fúnScandal

Nthathi Moshesh(bíi ni ọjọ́ kejìdínlógbọ̀n oṣù kẹjọ ọdún 1969) jẹ́ òṣèré ni orílẹ̀ èdè South Áfríkà. Wọn yàn kalẹ̀ fún àmì ẹ̀yẹ Africa Movie Academy Award for Best Actress in a Supporting Role ni ọdún 2016

Iṣẹ́[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Nthathi tí kópa nínú àwọn eré bíi Soldier Soldier, Home Affairs àti Human Cargo.[1] Ní ọdún 2014, ó darapọ̀ mọ́ àwọn òṣèré fún èrè Saint and Sinners Soap[2]. Ní ọdún 2015 ó kópa nínú eré Ayanda tí wọn sì ṣe ìfihàn rẹ ayẹyẹ Durban International Film Festival[3]. Ipa rẹ̀ nínú eré yí lọ fàá tí wọ́n fi yàán kalẹ̀ fún àmì ẹ̀yẹ tí òṣèré bìnrin to dára jù lọ láti ọdo Africa Movie Academy Award[4]. Ní ọdún 2016, ó gbà àmì ẹ̀yẹ gẹ́gẹ́ bí òṣèré bìnrin to dára jù lọ láti ọ̀dọ̀ South African Film and Television Awards[5]. Leyin ikú òṣèré Mary Makgatho, Nthathi sọ̀rọ̀ nípa iṣẹ́ ribiti tí òṣèré na ṣe kí ó tó kú.[6]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "It’s not about you, but what you represent' - Nthati Moshesh". ENCA. August 16, 2013. Archived from the original on 2014-06-26. Retrieved 2017-11-12. 
  2. BULELWA, DAYIMANI (August 7, 2014). "My acting career’s been revived". destinyconnect.com. Archived from the original on 2018-03-27. Retrieved 2017-11-12. 
  3. "Movie starring OC Ukeje to open Durban Film Festival". Pulse. June 8, 2015. Retrieved 2017-11-12. 
  4. "AMAA 2016: Adesua Etomi, OC Ukeje set to make history again". Vanguard. Retrieved 2017-11-12. 
  5. "Local film and TV stars celebrated at Saftas". Citizen. March 20, 2016. Retrieved 2017-11-12. 
  6. "Nthati Moshesh pays tribute to Mary Makgatho". Channel 24. Retrieved 2017-11-12.