Shaleen Surtie-Richards

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Shaleen Surtie-Richards
Ọjọ́ìbíOṣù Kàrún 7, 1955 (1955-05-07) (ọmọ ọdún 68)
Upington, Cape Province, South Africa
Orílẹ̀-èdèSouth African
Iṣẹ́Actress, talk show host
Ìgbà iṣẹ́1974-present
Gbajúmọ̀ fúnFiela se kind, Egoli: Place of Gold, Supersterre

Shaleen Surtie-Richards (bíi ni ọjọ́ keje, oṣù karùn-ún, ọdún 1955)[1] jẹ́ òṣèré ni orílẹ̀ èdè South Áfríkà. Ó gbajúmọ̀ fún ipá tí ó kó nínú eré Fiela se Kind ni ọdún 1988 àti Egoli: Place of Gold.

Ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀ ayé rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bíi Shaleen sí ìlú Upingtong ni orílẹ̀ èdè South Áfríkà. Bàbá rẹ̀ jẹ́ olùdarí ilé ẹ̀kọ́, ìyá rẹ sì ju olùkọ́.[2][3] Surtie-Richards jẹ́ olùkọ́ fún àwọn ọmọdé láti ọdún 1974 di ọdún 1984. Ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ eré ṣíṣe ni ọdún 1984.

Iṣẹ́[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Surtie-Richard ṣe adájọ́ fún ètò Supersterre láti ọdún 2006 di ọdún 2010.

Fíìmù[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Fiela se Kind (1988)
  • Mama Jack (2005)
  • Egoli: Afrikaners Is Plesierig (2010)
  • Knysna (2014)
  • Treurgrond (2015)
  • Twee Grade van Moord (2016)
  • Vaselinetjie (2017)

Eré orí Telefiisonu[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Egoli: Place of Gold
  • 7de Laan
  • Villa Rosa
  • Generations

Eré orí itage[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Aardklop Festival[4]
  • Klein Karoo Festival[5]
  • Grahamstown Festival
  • Suidoosterfees [6]
  • Edinburgh Fringe Festival.[7]

Àwọn àmì ẹyẹ tó ti gbà[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Surtie-Richard tí gbà àmì ẹ̀yẹ tó lé ní ogójì. Ó gbà àmì ẹ̀yẹ gẹ́gẹ́ bíi òṣèré tó dára jù lọ láti ọ̀dọ̀ Fleur du Cap Theatre Awards fún ipá Hester tí ó kó nínú eré Hallo en Koebaai (Hello and Goodbye). Ní ọdún 2009, ó gbà ẹ̀bùn míràn láti ọ̀dọ̀ Fleur du Cap Awards fún ipá tí ó kó nínú eré Shirley Valentine ni ọdún 2008. Ní ọdún 2018, ó gbà ẹ̀bùn eléré tó gbajúmọ̀ láti ọ̀dọ̀ Herrie Prize níbi ayẹyẹ Klein Karoo Arts Festival.[8] Ní ọdún 2014, ó gbà ẹ̀bùn fún akitiyan rẹ tí ó tí kó nínú àwọn eré bíi Egoli: Place of Gold, Generations, and 7de Laan.[9] Wọn yàán kalẹ̀ fún ẹ̀bùn òṣèré tó tayọ julọ ni ọdún 2014.[10] O gba ebun láti ọ̀dọ̀ Naledi Theater Awards ni ọdún 2015.[11]

Àwọn itokasi[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Shaleen Surtie-Richards". TVSA: Television South Africa. TVSA. Retrieved 5 December 2016. 
  2. De Villiers, Basheerah (12 December 2014). "'What you see is what you get; I cannot be pretentious,' says Shaleen Surtie-Richards". The South African. http://www.thesouthafrican.com/what-you-see-is-what-you-get-i-cannot-be-pretentious-says-shaleen-surtie-richards/. Retrieved 5 December 2016. 
  3. Cohen, Robyn (14 March 2010). "Veteran of the Fleur du Caps; Shaleen Surtie-Richards is set to be a highlight of the awards at which she made history 26 years ago". Argus Weekend (South Africa). 
  4. "Drama, farce centre stage at fest". The Pretoria News. 4 August 2015. 
  5. Cavernelis, Dennis (22 April 2008). "Bye's Yellowman wins best KKNK production". Cape Times (Independent Online (South Africa)). 
  6. "Diverse Drama at Suidoosterfees". The Argus (Cape Town) (Independent Online (South Africa)). 16 April 2016. 
  7. Doudai, Naomi (31 August 1989). "Edinburgh Takes the Stage". Jerusalem Post. 
  8. Cavernelis, Dennis (22 April 2008). "Bye's Yellowman wins best KKNK production". Cape Times (Independent Online (South Africa)). 
  9. "Isibaya wins big at Royalty Soapie Awards". Channel24 (24.com). 10 March 2014. http://www.channel24.co.za/TV/News/Isibaya-wins-big-at-Royalty-Soapie-Awards-20140310. Retrieved 5 December 2016. 
  10. "Nominees announced for the Royalty Soapie Awards". Channel24 (24.com). 18 February 2014. http://www.channel24.co.za/TV/News/Nominees-announced-for-the-Royalty-Soapie-Awards-20140218. Retrieved 5 December 2016. 
  11. "Marikana the Musical triumphs with six Naledi Theatre Awards". News24 (24.com). 15 April 2015. http://www.news24.com/Archives/City-Press/Marikana-the-Musical-triumphs-with-six-Naledi-Theatre-Awards-20150430. Retrieved 5 December 2016.