Okoẹrú

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
(Àtúnjúwe láti Slavery)
Àwòrán gbígbẹ́ tó ṣe àfihàn àwọn erú pẹ̀lú ìgbèkùn ní Ilẹ̀ọba Rómù, ní Smyrna, 200 CE.

Okoẹrú jẹ́ ìṣe ayé àtijọ́ tí àwọn ènìyàn kan máa ń ṣe káràkátà ọmọ ènìyàn mìíràn fún àwọn alágbára tàbí àwọn òyìnbó amúnisìn. Nínú okowò ẹrú, ọmọ ènìyàn ni ọjà tí wọ́n ń tà. Wọ́n máa ń kó àwọn ènìyàn tí wọ́n tà lẹ́rú lọ ṣiṣẹ́ oko àti àwọn ìṣe líle ni ìlú òyìnbó. Àwọn tí wọ́n bá kò lẹ́rú kì í ní òmìnira kankan bẹ́ẹ̀ sì ni wọ́n fi wọ́n ṣiṣé ní tipátipá.[1][2][3]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Laura Brace (2004). The Politics of Property: Labour, Freedom and Belonging. Edinburgh University Press. pp. 162–. ISBN 978-0-7486-1535-3. https://books.google.com/books?id=osZnIiqDd4sC&pg=PA162. Retrieved May 31, 2012. 
  2. Kevin Bales (2004). New Slavery: A Reference Handbook. ABC-CLIO. p. 4. ISBN 978-1-85109-815-6. https://books.google.com/books?id=8Cw6EsO59aYC&pg=PA4. Retrieved 2016-02-11. 
  3. Shelley K. White; Jonathan M. White; Kathleen Odell Korgen (27 May 2014). Sociologists in Action on Inequalities: Race, Class, Gender, and Sexuality. SAGE Publications. p. 43. ISBN 978-1-4833-1147-0. https://books.google.com/books?id=GsruAwAAQBAJ&pg=PA43.