Wolé Olánipẹ̀kun

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Olóye Wọlé Olánipẹ̀kuntí wọ́n bí ní Ọjọ́ kejìdínlógún oṣù kọkànlá ọdún 1951 (November,18th 1951)jẹ́ Adájọ́ ọmọ Yorùbá láti orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Òun ni Ààrẹ Ẹgbẹ́ Ìgbìmọ̀ Àwọn Adájọ́ Nigeria Bar Association

Ìgbà èwe[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Olóye Wọlé Olánipẹ̀kun lọ sí Ilé-Ìwè Amoye Grammar School ni Íkẹ́rẹ́-Ekiti,Ípìnlẹ́ Ekiti State. Wọlé,parí ẹ̀kọ̀ mewa West Africa School Certificate ni Ilésa Girama kí ó to rékọ́já si gbogbo gbo University of Lagos, Nïbi tï oti gba oyê kèkerê nínú ise òfin.[1][2] A pee si inú îgbîmọ́ àwọn adájọ̀ Call to the bar ni orîlẹ́ èdè Naijiria ni Odún 1976. Ni Odún 1991 ó di Agbẹjọ́ró Àgbà fún Ìpínlẹ̀ Ondo . Ó wa ni Ipó yi fún Odûn Mêjî gbàko. Ni odún 2002, wọ́n yan si ipò gẹ́gẹ́bí Ààrẹ fún Nigerian Bar Association.[3]   .[4] Láti odún 2004 si 2006 ó jé Ògá àgàbà Ìgbìmò àti Olùdárí fún Yunifásítì Ìlú-Ìbàdàn .[5][6]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Wole Olanipekun - INFORMATION NIGERIA". informationng.com. Retrieved 25 April 2015. 
  2. "Alumni, students urge N’Assembly to disregard UNILAG bill". The Punch - Nigeria's Most Widely Read Newspaper. Archived from the original on 16 September 2012. Retrieved 25 April 2015. 
  3. "Celebrating Wole Olanipekun at 59 , Articles - THISDAY LIVE". thisdaylive.com. Archived from the original on 30 April 2012. Retrieved 25 April 2015. 
  4. "Sofola emerges Body of Benchers’ chairman". The Punch - Nigeria's Most Widely Read Newspaper. Archived from the original on 3 May 2012. Retrieved 25 April 2015. 
  5. John Austin Unachukwu. "UI honours ex-NBA chief Ọlánípẹ̀kun". The Nation. Retrieved 25 April 2015. 
  6. "Forget Past Injustices Olanipekun Tells UI VC, Articles - THISDAY LIVE". thisdaylive.com. Archived from the original on 19 November 2015. Retrieved 25 April 2015.