Amin Yop Christopher

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Amin Yop Christopher (tí a bí ní ọjọ́ kefà, osù kejìlá, ọdún 1993) jẹ́ ọmọ orílè-èdè Naijiria tó ń gbá bọ́ọ̀lù badminton.[1] Ó ti kópa nínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìdíje ní ilè yìí àti nilẹ̀ òkèrè. Ó gbégbá orókè nínú ìdíje Rabat ti ilẹ̀ Africa tó wáyé ní ọdún 2019, ní Casablanca, ní Morocco.[2][3]

Àwọn àṣeyọrí rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ìdíje ti ilẹ̀ Africa[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Àdàpọ̀

Year Venue Partner Opponent Score Result
2019 Alfred Diete-Spiff Centre,

Port Harcourt, Nigeria

Nàìjíríà Chineye Ibere Nàìjíríà Dorcas Ajoke Adesokan

Nàìjíríà Uchechukwu Deborah Ukeh

14–21, 22–20, 17–21 Silver Silver

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Player: Amin Yop Christopher". bwfbadminton.com. Badminton World Federation. Retrieved 5 July 2020. 
  2. Shittu, Mudashiru (30 August 2019). "2019 African Games: Nigeria Badminton Scorecard". wildflowers.com.ng. Archived from the original on 5 July 2020. Retrieved 5 July 2020. 
  3. Shittu, Mudashiru (30 August 2019). "2019 African Games: Nigeria Badminton Scorecard". wildflowers.com.ng. Archived from the original on 5 July 2020. Retrieved 5 July 2020.