Asake

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Ahmed Ololade tí wọ́n bí ni ojó kankànlá oṣú kẹfà, ọdún 1995, tí orúkọ ìnágìjẹ rẹ̀ ǹjè Asake jẹ́ olórin Afrobeats láti orílẹ́ èdè Nàìjíríà.[1] Ójẹ́ olórin lábẹ́ àkóso YBNL Nation.[2]

Iṣẹ́[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Asake kẹ́kọ̀ọ́ Theatre & Performing arts ní Obafemi Awolowo University, Ile-Ife, Osun state. Iṣẹ orin rẹ di gbajumọ ni ọdun 2020, nigbati o se àgbéjáde ere ọfẹ kan ti akole rẹ̀ jẹ́ 'Mr Money'.

Awọn itọkasi[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]