Esther Oluremi Obasanjo

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Esther Oluremi Obasanjo
First Lady of Nigeria
In role
13 February 1976 – 1 October 1979
Head of StateOlusegun Obasanjo
AsíwájúAjoke Muhammed
Arọ́pòHadiza Shagari
Second Lady of Nigeria
In role
29 July 1975 – 13 February 1976
Chief of StaffOlusegun Obasanjo
First LadyAjoke Muhammed
AsíwájúAnne Wey
Arọ́pòHajia Binta Yar'Adua
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí
Oluremi Akinlawon

1941 (ọmọ ọdún 82–83)
Ọmọorílẹ̀-èdèNigerian
(Àwọn) olólùfẹ́
Olusegun Obasanjo
(m. 1963; div. 1976)
Àwọn ọmọ5; including Iyabo Obasanjo

Esther Oluremi Obasanjo tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Màmá Ìyábọ̀ ni ó ti fìgbà kan jẹ́ obìnrin àkọ́kọ́ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Òun ni ó jẹ́ ìyàwó tẹ́lẹ̀ rí fún Olusegun Obasanjo tí ó jẹ́ ààrẹ tẹ́lẹ̀ rí fún orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[1]

Ìgbésí ayé[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Olúrẹ̀mí Akínlàwọ́n jẹ́ ọmọ Mrs. Alice Akinlawon (nee Ogunlaja).[2] Ó pàdé Olúṣẹ́gun Ọbásanjọ́ ní inú ilé-ìjọsìn Owu Baptist Church ní déédé ọmọ ọdún mẹ́rìndìnlógún.[3] Wọ́n ṣe ìgbeyàwó ní ọjọ́ kejìlélógún oṣù kẹfà ọdún 1963 ní Camberwell Green Registry, SE London nígbà tí ó di ọmọ ọdún mọ́kànlélógún láì jẹ́ kí àwọn òbí tàbí ẹbí wọn ó mọ̀ nípa rẹ̀.[1][4] Olúrẹ̀mí kẹ́kọ̀ọ́ ní ilé-ẹ̀kọ́ institutional management ní ìlú London.[4] O di obìnrin àkọ́kọ́ ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà lẹ́yìn ìdìtẹ̀gbàjọba tí ó sì fa iku Ààrẹ ìgbà náà, ọ̀gágun Murtala Mahammed tí ó sì gbé ọkọ rẹ̀ Oluṣẹgun Ọbasnajọ dé ipò Ààrẹ [1] [4]

Iṣẹ rẹ[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ní ọdún 2008, Ọbasanjọ ṣe àtẹ́jadè ìwé ìtàn -akọọlẹ igbesi aye kan tí àkọlé rẹ jẹ Bitter-Sweet: Ìgbésí ayé Mi pẹ̀lú Ọbasanjọ nínú èyí tí o ṣe àpèjúwe àwọn ìrírí ìgbésí ayé rẹ pẹ̀lú Olusegun Obasanjo tí n ṣàpèjúwe rẹ bi obìnrin oníwà-ipá. Ó ṣe àpèjúwe ara rẹ jẹ “yangan ni ọna arekereke” ó má múra ní àwọn aṣọ ìbílè.

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

 

Àdàkọ:S-honÀdàkọ:S-end
Preceded by
Ajoke Muhammed
First Lady of Nigeria
1976 – 29 July 1979
Succeeded by
Hadiza Shagari