Ivor Agyeman-Duah

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Ivor Agyeman-Duah
Ọjọ́ìbí1966 (ọmọ ọdún 57–58)
Kumasi, Ghana
Orílẹ̀-èdèGhanaian
Ọmọ orílẹ̀-èdèGhanaian
Ẹ̀kọ́Ìdàgbàsóké óró ájé látí ílé ékó ìlá óòrùn àtí èkó Africa (SOAS), Yúnífásítì tí London
Iléẹ̀kọ́ gígaUniversity of Wales
Iṣẹ́Onmówé àtí onkówé

Ivor Agyeman-Duah (ti a bi òdún 1966) jẹ ọnmọwé ọ́mọ́ ilu Ghana kan, ònímọ̀-ọ́rọ́-àjé, ònkọ́wé, olòótú àtí ólúdárí fìímù. Ó tì ṣìṣẹ́ ní íṣẹ́ íjọ́bá ìlú Ghana ó si ṣiṣẹ bi òlùdàmọ̀rán lórì ètò ìmùlò ìdàgbàsókè.

Ígbésíàyé[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ábiị Ivor Agyeman-Duah ni Kumasi, Ghana, ni ọdun 1966, à sì sọ́ l'orukọ lẹhin ọ̀rẹ́ baba rẹ, akoitan Ilu Gẹẹsi Ivor Wilks .

Agyeman-Duah ní òyé MA látì Ílè-ẹ̀kọ̀ giga ti Wales, MSc ní Ìdàgbàsóké Ìṣòwò látì Ile-iwe ti Ila-oorun ati Awọn ẹkọ Afirika (SOAS), University of London ati MSc kan ninu Itan-akọọlẹ ti Awọn ibatan Kariaye lati Ile-iwe London ti Imọ-ọrọ ati Imọ-ọrọ Oṣelu . Òún ní òlùdásìlè àtí Òlùdàrì Ìlé-ìṣẹ́ fún Ísọ́dọ́tún Ọ́pọ́lọ́, ágbárí Àfíhán Àwùjọ́ ní ́Ghana.

Látì 2009 sí 2014 o jẹ oludamoran pataki si Àáré John Agyekum Kufuor lórì ífówósówópó ìdàgbàsòké àgbáyé, àtí nì àgbárá yíì ṣíṣẹ̀ pẹ́lù Eto Ounje Agbaye ni Kenya ati Etiopia ati ajọ-iṣẹ imulẹ alafia agbaye ti Interpeace tí ó wà ní Geneva. Ó tí ṣè íṣẹ́ fún Ílé Ìfówópámó Agbáyé àtí Ìlé Ífówópámó Àgbáyé ní Washington, DC. Agyeman-Duah nígbákán tí jẹ́ ọlórí àkọsílẹ àlámọrí ní Ghana Embassy, Washington, DC, àtí lẹ́hínnà Ólúdámọràn Àṣà àtí Ìbáráẹ́nísọ̀rọ̀ ní Ìlé-ìṣẹ́ gígá Ghana ní Ìlú Lọndọu, àtí pé ó tún jẹ álámọ́ràn tì Ílè-íṣẹ́ Áfríkà fún Ìyìpádà Ìṣòwò . Ó tún tì ṣè awọ́n ìdàpò ní WEB Du Bois Institute for African and African American Research ni Harvard University ati ki o je òlùgbé òmówé Hilary ati Trinity ni Exeter College, Oxford .

Ó nṣíṣé lọ́wọ́ ní àwọ́n áàyè ìwé-kíkọ́ àtĺ àṣà, Agyeman-Duah ti kọ tabi ṣé àtúnkọ̀ ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ àwọ́n àtẹ́jádé – pẹ̀lú 2014's Crucible of the Ages: Essays ní ólá tí Wole Soyinka ni 80, ìwé tí á ṣé àpèjúwé bì “iwọn akoko ti o yẹ pẹlu òlá n lá, ìdíyélé àtí pàtàkì ọ́gbọ́n pátàkì", ìfíhán àwón òlúkópá pẹ̀́lù Ngugi wa Thiong'o, Nadine Gordimer, Margaret Busby, Toni Morrison, Ama Ata Aidoo, Henry Louis Gates, Jr., Kwame Anthony Appiah, Ali Mazrui, Derek Walcott, Atukwei Okai, Cameron Duodu, Toyin Falola, Osei Tutu II (ọba Asante), John Mahama ati f Thabo Mbeki . Agyeman-Duah ṣíṣẹ̀ bì Òlùdámóràn Àfíhán Ìdàgbàsóké fún ílé ísé tó tá éká sí Eko,Lumina Foundation,[1] eyiti o fi idi Wole Soyinka Prize fun Litireso ni Afirika múlè, átì pè ó jẹ́ Àlága 2014–15 ti Litireso ti Millennium Excellence Foundation.

Ó kọ́, ṣé itọ́sọ́nà àtí ágbèjádè áwọ́n fíímù áláwórán tẹ́lìfísíọnù méjì - Yaa Asantewaa: Ìṣílọ́ tí Ọ́bá Prempeh àtí Ákíkánjú tí Áyábá Áfíríkà kán, tí á ṣé àfíhán ní Ghana ní 2001, àtí Ípádal Ọ́bá kán sí Seychelles, èyítí ó hàn ní Ìlé Chatham ní ọ̀dún 2015. Agyeman-Duah tún jẹ̀ àlámọ́rán ìtán sí tíátá gbòóji 2001 ti Margaret Busby nipa Yaa Asantewaa ( Yaa Asantewaa – Warrior Queen ).

Ìdágbásóké ọrọ-ájé àtí ìfówósówópó àgbáyé[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Lọ́wọ́lọ́wọ́, Agyeman-Duah jẹ́ Ásíwájú Ísé àgbésé /Álákósó lòrì ọ̀kán nínú ACET-Ílé-íṣẹ́ Norwegian fún Ìfówósówópó Ìdàgbàsóké Káríáyé àtí àwọ́n ìṣẹ́ ílé ífówópámọ́ Àgbáyé- Íbáṣèpọ́ Ílànà fún Ìdàgbàsóké Àpá Àládání & Ìdàgbà. Ó tún n ṣíṣẹ́ ní ìṣẹ́ ètò ìmúlò ètò-ọ̀rọ̀ ìmọ̀-ẹ́rọ́ lórí ìdágbásóké ní Rwanda, ti órílẹ́-édé jé ètó ìtàn-ákọ̀ọ́lẹ́ ìtán-àkọ̀ọ́lẹ̀ rẹ̀ “Àwọ́n Tí ò dárá”. Ó sì tí jẹ́ ẹ́gbẹ́ Ìwádí Ọ́dòódun ní Àwọ́n Íkẹ́kọ́ Ìdágbásóké ní Ílé-ìwè tì Ílá-óòrùn àtí Àwọ́n Ìkẹ́kọ́ Africa, Lọndọn, àtí òkán nínù Ọ́mọ́ ẹ́gbẹ́ Álákósó ti Ile ọnọ ti Ghana ati Igbimọ Ílé àràbàrà . Làárín ọ́dún 2017 àtí 2018, ó ṣìṣẹ́ bí Òlùdàmọ̀rán Ìláná Ìdàgbàsóké fun Institute for Fiscal Studies ni Accra, Ghana, lórì àwọ́n ìgbéléwọ́n ìgbèkàlẹ̀ fún àgbàwí ètò ímúlò ínáwó.

Lati 2010 si 2012, o jẹ oludari ti Alliance for Africa Foundation ti o da ni Accra, àgbárí ọkèẹ́rè tí kìí ṣé tí ìjọ́bá tí á ṣètò nípásẹ̀ Ìgbímọ́ Ìlú Milan, Lombardy Regional Government ati Expo 2015 ti Italy tí ón wò ètó-ẹ́kọ́ átí ìdàgbàsóké àwọ́n àmáyédérùn, pẹ́lù áséìṣẹ́ tí àtúnṣétò tí ìlé-íṣẹ́ kọkọ ní Liberia.

Ó tí ṣíṣẹ́ lórí ọ̀pọ́lọ́pọ́ áwọ́n ìṣẹ́ akánṣé àgbáyé làárín ọ̀dún 2005 àtí 2014 gẹ́gẹ́bí ọ́mó ẹ́gbẹ́ tí nẹtiwọki kán tí òn wò ípá tí àwọ́n àwùjọ́ Ìlú Afirika tín gbé ìlụ́ òk̀ẹ̀ẹ́rè ní ìdàgbàsóké ètò-ọ̀rọ̀ ní Ìlé ìfówópámó Agbaye ni Washington, DC, ó sí jé àpá ègbé kán fún kíkọ́ ìlé ágbárá ìlé ìfówopámó fun ísé àṣẹ́ ágbésé ìbílé lórí ìní àjé. [2]

Ó jẹ́ ònímọ́rán sí ìṣẹ́ àkànṣé àṣà Aluka tí Andrew Mellon Foundation tí New York àtí pé ó tún jé álábádásílé, nípásẹ́ inawo kóríyá, èró ìwé-ẹ́rí $500,000 kán ní Ílé-ẹ́kọ́ gígà Exeter tí Ìlé-ẹ́kọ́ gígá tí Oxford fún àwọ́n ọ́mọ́ ìlé-íwé gígá tí Ghana - Áwọ́n ẹ́gbẹ́ John Kufuor. Ó tí ṣíṣẹ́ ní Côte d'Ivoire fún Ìjọ́bá àtí àwọ́n ọ́já àràmádá bí ọ́mọ́ ẹ́gbẹ́ ìwádìí ìmọ̀ràn àtí ásíwájú ònkọ́wé lórì íṣélọ̀pọ̀ àtí àwọ́n ọ́já rìrọ̀ tìtà: Àwọ́n ìhámọ́ àtí Ìmúdánílójú tí Kókó àtí àwọ́n ápákán Kòfì ní ágbégbé Yamoussoukro àtí àwọ́n ìhámọ́ àtí Ìmúdánílójú tí Rice. [3] Ni Ghana àtí Liberia, ó ní ípá pẹ̀lù Washington, DC- ajọ́sépọ́ látí gé ébí àtí òsì ní Africa àtí Michigan State University .

Gẹ́gẹ́bí òjògbón ìdàgbàsòké, Agyeman-Duah tí rín írín-àjò ó sì ṣìṣẹ́ ńi àwọ́n òrílẹ́-èdè 25 Africa àtí Asia (pàápàá àpá gúúsú ílá-óòrùn) áwọ́n órílẹ́-èdè lórì íṣẹ́ ètò ímúlò ìdàgbàsòkè pẹ́lú ìjábọ̀ tí á tẹ́jádé tí àbájádé ìmúsé ètò ímúló ọ́dún mẹ́wà àkọ́kọ́ tí àpéjọ́ Káríáyé tí Tokyo lórí Ìdàgbàsòké Africa.

Ó jẹ́ àpákàn égbẹ́ àwọ́n ọ̀jọ̀gbọ́n, àwọ́n òlùṣé ètò ìmúló àtí àwọ́n álámọjà ìdàgbàsòké tí ápéjọ́ íwádì àtì ìwàdì Africa ní Washington, DC, tí á pápọ̀ látí ṣẹ àyẹ̀wò ètò ìmùlò àjèjì tí Àáré US George W. Bush tí Africa, lẹ́hínnà tí á gbéjàdè bì Ṣíṣáyẹ́wó Ímúló Africa ti George Bush's Africa àtí àwọ́n dídábá fún Barrack Obama (Bloomington, Indiana: i Universe, 2009) àtí Àkópọ́ Ímúló Africa tí Barrack Obama (American University Press, 2011). [4]

Ájé àsà/ Ísé ònà lítírésọ[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Fún bí ọdun mẹwa lé séyín, Agyeman-Duah tí ṣíṣẹ́ pẹ̀lù Nobel laureate tí Náìjíríá ní Literature, Wole Soyinka lórí ọ̀pọ́lọ̀pọ́ àwọ́n íṣẹ́ àkànṣè pẹ̀lú gégébì ólúdárì ẹ́gbẹ́ tì ón sé ìdánwó Wole Soyinka Foundation pẹ̀lú University of Johannesburg ní South Africa . Àwọ́n ólùkòwé tí ó ní ìtárá ní ágbégbé gúùsù Africa ní á fún ní ìmọ̀rán, Soyinka si kó ọ̀pọ̀lọ̀pọ̀ áwọ́n ìkẹ́kọ́ rẹ̀, Long Walk si Mandeland, gẹ́gẹ́bí ápákán tí ètò nàá. [5] [6] Bákánná ní wón sísé pápò lórí órísírísí èkọ́ tí gbógbó ènìyàn sé ní University Oxford, nínù èyí tí Soyinka tí kédé pé òún yòó yá Kàádí Green US sí wéwé tí Donald Trump bá bórí nínù ìbò. [7]

Lá pàpò pèlú Lucy Newlyn, òjógbón télérì ní St. Edmund Hall, Oxford, Agyeman-Duah jé álájó pọlóngo Soyinka ní idíjè yìyán tì akéwì Oxford Professorship. Bí ó tìlè jé pẹ wón kúnà, síbè àtíléyín wá látì awón éní àámí ágbáyé bí Archibishop ìgbàkán rí tí Canterbury Rowan Williams, Ọlúdarí télé tí Liberty Baroness Chakrabari, tí Kennington, Ọjògbón ákéwì tí US Rita Dove, the Booker Prize laureate Ben Okri OBE, àtí ákéwì British-Jamaican Benjamin Zephaniah, ìlànà ìpólóngó wón àtí àwón ìfíyèsí wón ní wón tè jádè bíì Kí ojìjì wón másè díkù – Wole Soyinka àkéwí Oxford Professorship. Ó sè àlàyè díè tí ọjọgbón àkéwí ádúláwò St. Lucian Nobel poet Derek Walcottsé yókúrò nínù idíjé kán nà ní awón ódún kán sehín tí ó túmò sí pé áàyè nà jé tí British, látì igbà tí Joseph Trapp ákéwì géèsii àtí àlùfa Anglican kókó gbáà ní ódún 1708, jú tí òkéèrè .[8]

Ní odún 2017, ó jé àjó àlápéjo (pèlú SOAS) fun ayeye odun karun din ni ogota ti Apejo Makerere tí Ọnkòwé Ílè ÁdúláwòUganda, ítàn ìjò náà ní odún 1962 tí èyìn ìjóbá ámúnísìn òjógbón mòókó mòóká tí, bí á sàpèjúwè nípá àràmàdà Kenya Ngugi wa Thiong'o, wà "ìṣọ́kán nípàsẹ̀ ìrán tí ó ṣéèṣẹ tí ọ̀jọ́ íwájú tí ó yátọ fún Ílè Ádúláwò. "[9]

Agyeman-Duah jé ólùtójú ìbèrè tí The John A Kufuor Museum àtí Presidential Library àtí ọkán lárá égbé tí o ́ dúnàdúrà ìdàgbásókè ámáyédérùn ní Yúnífásìtì Sáyénsì àtí Ìmò Kwame Nkrumah ní Kumasi àtí ní Yúnífásítì tí Ghana, Legon. Sí bè sí ní wíwà ní áàye ètò imúlo àtí èkó òfé, Agyeman-Duah sì tún ní ìsé tó yàtó ní onà ìtàgé àtí ísè ìròyìn. Ó kó fún Panos Institute tí orísùn e wa ní London, Ìwò Óòrun Africa, New African àtí àtúnko Some African Voices of Our Time (2002), àwón àkójópó ìbáráénìsòró pèlú àwón ọnkówé Africa.

Jéjé bì ónsé àgbéléwó ìwé ìtàn àtí légbéè híhàn lórì àwón órísírísí ètò bí BBC, VOA àtí àwón éèto òkèéré bí òjògbón ìdàgbàsóké àtí òlùyánjú, Agyeman-Duah jé ómó égbé gbóòji fun BBC àtí ìwé ìtàn PBS TV - Into Africa and Wonders of the African World, tí ásíwájú ónmówè African-American Henry Louis Gates Jr gbékálè. Agyeman-Duah sé ìpìlèsè àdèhùn àtí ètò ìgbéjádé íkéhìn fún Discovery Channel ní Ghana: Presidential Tour. Ó jé ọnímórán ìgbéjádé sí Moving Vision TV, Wales, fún The Kingdom of Ashanti àtí ìgbéjádé Yaa Asantewaa: The Heroism of an African Queen. Ónímóraln fún Óbá tí Asante, Otumfuo Nana Osei Tutu II, lórí íbéwó ré sí érékúsù Seychelles, Agyeman-Duah tèlé pèlú Ípádábó Óbá kán sí Seychelles.[10]

Agyeman-Duah sísé pèlú Adzido Pan African Dance Ensemble (fún ìgbìmo ona tí England sé ágbátèrù) $2-million àtí sísé éré ìtágé álágbéká ìwoọn ódún kán (ní Ílé érẹ́ West Yorkshire ní Leeds, Manchester Opera House, Alexander Theatre, Birmingham and Edinburgh Festival Theatre), Accra àtí Kumasi tí, Yaa Asantewaa Warrior Queen. Ísé ìgbéjádé éléníyàn áàdótá yí ní ólùdásílè àtí ólùdárí ísé ónà tí Carnival Messiah, Geraldine Connor[11] jé ólùtóná.

Ní ódún 2014, ó jé álásé ó nsé méjí nínù éré ìtàgé Soyinka, Ake: The Years of Childhood and Childe Internationale. Agyeman-Duah sì tún jé ólùtójú po ní 2004 (pèlú ónítàn Kwaku Fosu Ansa àtí Myrtis Beddla) ní Washington, DC fún tì ìfíhàn Ancient Traditions and Contemporary Forms. Ó sísé télé ní oko agbáíyé tí Pan-African Historical Theatre Project (Panafest).

Yíyán aléjọ/Íkówè gbángbán[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

    • Globalisation and Africa’s Unfinished Agenda- Responding to Thandika Mkandawire, Macalester College, St. Paul's, Minnesota, US, 1998.
    • Africa in a Renaissance Mood- Ghana in the Early Years of the C21st, All-University Lecture, California State University, Pomona, 2004.
    • Pan-Africanism Caribbean Connections, Santo Domingo, Dominican Republic, 2005.
    • Travelling Abroad but Having Home in Mind- Culture, the Arts and National Identity, Fifty Years of Ghana’s Independence, University of Ghana, Legon, 2007.
    • Beyond the Miracle of the Han River-Some Pro-Growth Philosophy in Korea’s Rural Development and Africa’s Search for Agricultural Stimulation, Seoul, Korea, Korea Institute for International Economic Policy, 2011.
    • Choices in a World of Strangers, Guest Speaker, The Great Hall, University of Ghana's Congregation - The College of Humanities, 2018.
    • Asante: Sustaining a Heritage and a Cultural Economy, 1st Opemso Lecture of the Asante Professionals Club, Kumasi, March 2019.

Ìtèjádé[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Between Faith & History: A Biography of J. A. Kufuor (three volumes), Ayebia Clarke Publishing Ltd, January 2007. ISBN 978-0954702397.[12]
  • Pilgrims of the Night: Development Challenges and Opportunities in Africa, 2011.
  • Africa a Miner's Canary Into the C21st: Essays on Economic Governance, foreword by Toyin Falola, 2013.
  • Telephone Conversations: A History of Telecommunications Economics and MTN in Ghana, 2020.

Bí Ólóòtù[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • The Asante Monarchy in Exile: Sojourn of King Prempeh I and Nana Yaa Asantewaa in Seychelles, 2000.
  • Kyerematen and Culture- The Kyerematen Memorial Lectures, 2001.
  • (With Peggy Appiah) Bu Me Be: Proverbs of the Akans, Introduction by Kwame Anthony Appiah, 2006.
  • An Economic History of Ghana: Reflections on a Half-Century of Challenges & Progress, Foreword by Wole Soyinka, 2008. ISBN 978-0955507984.
  • (With Ogochukwu Promise) Crucible of the Ages: Essays in Honour of Wole Soyinka at 80, 2014.[13]
  • All The Good Things Around Us: An Anthology of African Short Stories, 2016. ISBN 978-0992843663
  • (With Lucy Newlyn) May Their Souls Never Shrink: Wole Soyinka and the Oxford Professorship of Poetry, 2016. ISBN 978-0992843670
  • The Gods Who Send Us Gifts: An Anthology of African Short Stories, Forewords by Wole Soyinka and Valerie Amos, 2017.
  • Death of An Empire- Kwame Nkrumah in Ghana and Africa - KSP Jantuah, 2017. ISBN 978-9988871468
  • (With Bill Buenar Puplampu) Africa in Search of Prosperity: Ishmael E. Yamson’s Essays on Development, Economics, Business, Finance and Economic Growth, 2017.
  • Between the Generations: An Anthology for Ama Ata Aidoo at 80, 2020.

Ápá Ìwè, ákósílé árókó àtí àtúnyéwò[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • "Yaa Asantewaa"; "Seychelles Islands", and "George Padmore", in Carole Boyce-Davies (ed.), The Encyclopedia of the African Diaspora, ABS-CLIO, Inc. Santa Barbara/Oxford, England, 2004.
  • "Themes in West African History. Edited by Emmanuel Akeampong, James Currey, England. 2005." Reviewed in African and Asian Studies Journal, Vol. 5, Nos 2–3 (Brill, Leiden).
  • "Female Circumcision and the Politics of Knowledge – African Women in Imperialist Discourses. Edited by Obioma Nnaemeka, Prager Publisher, Connecticut. 2006". African and Asian Studies, Vol. 5, Nos 3–4.
  • America Behind the Color Line: Dialogue with Africans Americans. Henry Louis Gates, Jnr. Warner Books, USA. African and Asian Studies Journal, Vol. 5, Nos 3–4.
  • "Chieftaincy in Ghana – Culture, Governance and Development. Edited by Irene K. Odotei and Albert K. Awedoba, Accra: Sub-Saharan Publishers, 2006". African Affairs (Royal African Society, London), 106 (425), 730–731.
  • "Peace Without Power: Ghana’s Foreign Policy 1957 – 1966. Kwesi Armah, Ghana Universities Press, Accra, 2004." International Affairs, Journal of The Royal Institute of International Affairs, Chatham House, London, 2007.
  • "You Must Set Forth at Dawn – A Memoir. Wole Soyinka. Methuen, London; 2006". International Affairs, Chatham House, 2007, London.
  • "The African Diaspora – African Origins and New World Identities. Edited by Isidore Okpewho, Carole Boyce Davies and Ali A. Mazrui. Indiana University Press, Indiana. 2001". African and Asian Studies Journal (September 2007), Brill, Leiden.
  • "East Asian Visions – Perspectives on Economic Development. Edited by Indermit Gill, Yukon Huang and Homi Kharas, World Bank, Washington, DC, 2007." Reviewed in International Affairs. Chatham House, London.
  • "Japan Rising – The Resurgence of Japanese Power and Purpose, Kenneth B. Pyle, Perseus Books, US." African and Asian Studies Journal, 2008.
  • "The Diaspora – Those Who Were Exiled from their Land." Asia–Africa Literature Journal, Jeonju, South Korea, 2008.
  • "Dambisa Moyo and the Aid Architecture," The New Legon Observer, Vol. 3, No. 11, September 2009.
  • "Conversations of Fathers and Daughters" (review of Fathers and Daughters- An Anthology of Exploration, edited by Ato Quayson, 2009), Transition, Indiana University Press, 2009.
  • “Culture, Communication and Socio-economic Development in Post-Colonial Ghana, in An Interdisciplinary Primer in African Studies, edited by Ishmael. I. Munene, Lexington Books, UK, 2011.
  • "Chinua Achebe's Gift to Humanity: A Useable Past", Africa Watch, New York, 2013.
  • "Albert Rene and The Modern History of Seychelles", Africa Today, Indiana University Press, 2015.
  • "Kofi Awoonor's The Promise of Hope", Africa Today, Indiana University Press, 2015.
  • "Seychelles Islands", in Toyin Falola and Jean-Jacques (eds), Africa- An Encyclopedia of Culture and Society, ABS-CLIO, California, US, 2016.
  • Malcolm X, Pan Africanism and Today's Blacks, Malcolm X and Africa by A. B. Assensoh and Yvette M. Alex-Assensoh, Cambria Press, UK, 2016

Ámí èyé, Ìdàpò, Ìfúnnì àtí òmó égbé ìkò[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Resident Fellow, Thomson Foundation Commonwealth Award, University of Wales. UK, 1994.
  • Asanteman Council award as chair of the local and international media committee on the 300-year anniversary of the founding of the West African Kingdom, 1996.
  • Visiting Writer and Researcher travelling within the US as a Fellow of the World Press Institute, Macalester College, St. Paul, Minnesota, USA.
  • International Visiting Fellowship of the US State Department, US, 1996.
  • Nzema Association of North America, Courage in Leadership for Outstanding Service to the Association, 2003.
  • Travel grant by the International Television Service of the US for the International Film Festival, San Francisco, California, 2003.
  • Phi Beta Delta International Scholar, awarded by the College of Arts and Letters, Pomona, 2003.
  • Resident Visiting Scholar, College of Arts and Letters, California State University, Pomona, 2003.
  • Distinguished Leadership and Scholarship Award of the Association of Third World Studies, US, 2004.[14]
  • Order of the Volta, Officer Division, Republic of Ghana, 2008.
  • Given a literary grant for Asia-Africa Literence Conference in Jeonju, North Province of Korea by the university and Government, 2008.
  • Resident Fellow, Centre for Regional Economic Studies, Korea Institute for International Economic Policy, Seoul, Korea, 2010.
  • Distinguished Friend of Oxford, University of Oxford, 2012.
  • Chair of the Jury, Millennium Excellence Foundation - Literature Category, 2015.
  • Member of the International Advisory Board, African Studies Centre, University of Oxford, 2018.
  • MTN Foundation Grant for Literature, 2020.

Ítókásí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. . Lagos.  Missing or empty |title= (help);
  2. World Bank, "Promoting Partnership with Traditional Authority Project" 2006. Retrieved 10 September 2020.
  3. Novel Commodities, Constraints and Redevelopment of the Cocoa and Coffee Sector in the Yamoussoukro District. 2010 Report co-written by Ivor Agyeman-Duah. Retrieved 10 September 2020.
  4. Emmanuel, Nikolas George, "book review of Assessing George W. Bush's Africa Policy 2009, by Abdul Karim Bangura (ed.)", African and Asian Studies, University of Copenhagen, 2010, p. 197. Retrieved 1 August 2021.
  5. Soyinka, Wole, Inaugural Public Lecture - Long Walk to Mandeland, 2017, University of Johannesburg. Retrieved 10 September 2020.
  6. Agyeman-Duah, Ivor (14 June 2018). "Nelson Mandela, Art and Memory". https://www.pmnewsnigeria.com/2018/06/14/nelson-mandela-art-and-memory/. 
  7. "Wole Soyinka destroys his Green Card as promised". 1 December 2016. https://www.myjoyonline.com/news/wole-soyinka-destroys-his-green-card-as-promised/. 
  8. Agyeman-Duah, Ivor, & Lucy Newlyn, May Their Shadows Never Shrink, 2017, Oxfordshire, UK: Ayebia Clarke Publishing. Retrieved 10 September 2020.
  9. Agyeman-Duah, Ivor, and Ogochukwu Promise, Crucible of the Ages - Essays in Honour of Wole Soyinka at 80, Ibadan: Bookcraft. Retrieved 10 September 2020.
  10. See Television documentary, The Return of a King to Seychelles, 2015, CIR production, Accra. Retrieved 10 September 2020.
  11. Adzido Pan African Ensemble, Yaa Asantewaa Warrior Queen, 2001. Retrieved 10 September 2020.
  12. "Ghana: Aliu, Soyinka to Launch Book On Kufuor". 3 January 2007. https://allafrica.com/stories/200701030741.html. 
  13. Assensoh, A. B.; Yvette M. Alex-Assensoh (25 June 2014). "Celebrating Soyinka at 80". New African. Retrieved 26 September 2020. 
  14. "AWARD FOR KUFOUR BIOGRAPHY". Ghana Studies Council Newsletter (17–18): 7. Summer–Fall 2005. http://www.ghanastudies.com/gsa/newsletter_04-05.pdf. Retrieved 26 September 2020. 

Àdàkọ:Authority control