Joshua Olufemi

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Joshua Olufemi (tí wọ́n bí ní ọjọ́ 22 oṣù keje, ọdún 1983) jẹ́ oṣìṣẹ́ orí ẹ̀rọ-ayélujára ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà àti olùdásílẹ̀ ìmọ̀-ẹ̀rọ fún àwọn ará ìlú. Òun ni olùdásílẹ̀ Dataphyte, òun sì ni olùdarí ètò Premiun Times Cntre for Investigative Journalism (èyí tí wọ́n ń pè báyìí ní The Centre for Journalism Innovation and Development - CJID).[1][2] Olufemi ni akọròyìn tó tún jẹ́ aṣojú Premium Times ní International Consortium of Investigative Journalists (ICIJ) fún ilé-iṣẹ́ atẹ̀wéjáde Panama Papers àti Paradise Papers.[3][4][5]

Ètò ẹ̀kọ́ àti iṣẹ́[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Olufemi kẹ́kọ̀ọ́ gboyè bachelor's degree nínú ẹ̀kọ́ Economics láti ilé ìwé gíga Olabisi Onabanjo ní ọdún 2005 àti oyè master's degree nínú ẹ̀kọ́ Measurement and Evaluation láti ilé-ìwé gíga University of Lagos ní ọdún 2013, kó tó lọ sí Said Business School ti University of Oxford, níbi tí ó ti gba oyè nínú ẹ̀kọ́ Global Financial Technology. O jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ Institute of Chartered Economists of Nigeria.[6]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Spotlight: Joshua Olufemi, Media Management Executive, Nigeria". NATIONAL ENDOWMENT FOR DEMOCRACY (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2019-12-13. Retrieved 2022-04-14. 
  2. "Premium Times Director selected for prestigious Reagan Fascell fellowship | Premium Times Nigeria" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2019-03-06. Retrieved 2022-04-14. 
  3. "The Panama Papers: About this project | ANCIR". panamapapers.investigativecenters.org. Retrieved 2022-04-14. 
  4. Shinovene, Shinovene (2016-04-26). "Dangotes offshore games in Panama Papers". Investigation Unit (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-04-14. 
  5. "#ParadisePapers: Saraki Violates Nigerian Law Again, Linked To Another Firm In Offshore Tax Haven". Sahara Reporters. 2017-11-06. Retrieved 2022-04-14. 
  6. "Joshua Olufemi's schedule for IPI World Congress 2018". ipiwoco2018.sched.com. Retrieved 2022-04-14.