Lérè Pàímọ́

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Lere Paimo
Ọjọ́ìbí(1939-11-19)19 Oṣù Kọkànlá 1939
Ogbomosho, Oyo State, Nigeria
Orílẹ̀-èdèNigerian
Orúkọ mírànEda Onile Ola
Ọmọ orílẹ̀-èdèNigerian
Iṣẹ́
  • Actor
  • filmmaker
  • producer
  • director
Ìgbà iṣẹ́1960–present
AwardsMFR

Lérè Pàímọ́, OFR (tí wọ́n bí ní oṣù kọkànlá ọdún 1939) jẹ́ gbajúmọ̀ òṣèré, olùdarí àti olóòtú sinimá àgbéléwò ọmọ bíbí ìlú Ògbómọ̀ṣọ́, ní ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ lórílẹ̀ èdè Nàìjíríà.[1] [2][3]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "People call me from everywhere to consult oracle for them –Lere Paimo". punchng.com. Archived from the original on 2015-02-08. Retrieved 2015-02-18. 
  2. "Nigeria's Top Website for News, Gossip, Comedy, Videos, Blogs, Events, Weddings, Nollywood, Celebs, Scoop and Games". Nigerian Entertainment Today. 2015-09-30. Retrieved 2019-12-17. 
  3. Adekunle, Jimoh Taofik (2019-11-20). "Ogbomosho: Elemosho, Soun and Crux of History". Republican Newspaper. Archived from the original on 2019-12-17. Retrieved 2019-12-17.