Lola Shoneyin

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Lola Shoneyin
Lola Shoneyin 2015
Ọjọ́ìbíTitilola Atinuke Alexandrah Shoneyin
(1974-02-26)26 Oṣù Kejì 1974
Ibadan, Oyo State, Nigeria
Orílẹ̀-èdèNigerian / British
Iṣẹ́Author
Olólùfẹ́Olaokun Soyinka
Parents
  • Chief Tinuoye (father)
  • Yetunde Shoneyin (mother)
Àwọn olùbátanAbraham Olayinka Okupe (Grandfather)
Ẹbí4 Children
AwardsLiterary Person Of The Year - 2018
Websitelolashoneyin.com

Lola Shoneyin (tí orúkọ àbísọ rẹ̀ ń jẹ́ Titilola Atinuke Alexandrah Shoneyin; ni wọ́n bí ni 26 February 1974, ní ìlú Ìbàdàn, ní Nàìjíríà) jẹ́ akéwì àti òǹkọ̀wé[1] tó ṣe àtẹ̀jáde ìwé àkọ́kọ́ rẹ̀, tí àkọ́lé rẹ̀ jẹ́ The Secret Lives of Baba Segi's Wives, ní UK, ní oṣù May ọdún 2010.[2] Shoneyin gbajúmọ̀ fún àwọn ewì rẹ̀ tó tayọ, ó ti kọ ewì mẹ́ta.[3] Ìṣọwọ́kọ̀wé rẹ̀ jẹ mọ́ ọ̀rọ̀-ìbálòpọ̀ obìnrin àti ìpèníjà tó jẹ́ mọ́ ilẹ̀ Afirika.[4] Ní April 2014, wọ́n dárúkọ rẹ̀ ní Hay Festival's Africa39 mọ́ àwọn òǹkọ̀wé ilẹ̀ Afirika tí ò tí ì wọ ọmọdún ogojì, pẹ̀lú tálẹ́ǹtì láti ṣàtúnṣe sí àwọn lítíréṣọ̀ ilẹ̀ Afirika.[5] Lola gba ẹ̀bùn PEN Award ní America[6] bákan náà ni ó gba ti Ken Saro-Wiwa Award fún ìtàn-àròsọ ní Nàìjíríà.[7] Ó wà lára àwọn tó máa gba ẹ̀bùn Orange Prize ní UK fún ìtàn-àròsọ àkọ́kọ́ rẹ̀, The Secret of Baba Segi's Wives, ní ọdún 2010.[8] Ìlú Eko ní Nàìjíríà ni ó ń gbé, níbi tíh ó ti máa ń ṣe Aké Arts and Book Festival ní ọdọọdún.[9] Ní ọdún 2017, Brittle Paper sọ ọ́ ní African Literary Person of the Year.[10]

Ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Titilola Atinuke Alexandrah Shoneyin sí ìlú Ìbàdàn, èyí tó jẹ́ olú-ìlú ti Ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́, tó wà ní apá Ìwọ̀-oòrùn ilẹ̀ Nàìjíríà, ní ọdún 1974. Òun ni àbígbẹ̀yìn àwọn ọmọ mẹ́fà àti ọmọbìnrin kan ṣoṣo. Àwọn òbí rẹ̀ Chief Tinuoye Shoneyin àti Mrs. Yetunde Shoneyin (née Okupe), jẹ́ ọmọ-ìlú Remo láti Ìpínlẹ̀ Ògùn.

Ìtàn ayé rẹ̀ àti ìrírí rẹ̀ ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ iṣẹ́ rẹ̀ dálé lórí, ó sọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ ohun tó rọ̀ mọ́ fíẹ́ ìyàwó púpọ̀ nínú ìwé alákọ̀ọ́kọ́ rẹ̀; bàbá-ìyá rẹ̀, Abraham Olayinka Okupe (1896-1976) ni olórí Iperu Remo, ó sì ní ìyàwó márùn-ún. Ó gorí oyè ní ọdún 1938, ó sì ṣaláìsí ní ọdún 1976.[11]

Iṣẹ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ìtàn-àròsọ[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ìtàn kékeré[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • "Woman in Her Season", Post Express Newspapers, 1996[19]

Ewì[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • So All the Time I was Sitting on an Egg (1998)[20]
  • Song of a River Bird, Ovalonion House (Nigeria, 2002)[21]
  • For the Love of Flight (2010)[22]

Ìwé àwọn ọmọdé[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Mayowa and the Masquerade, July 2010, published in the US in 2020[20]

Iṣẹ́ akada ti Lola Shoneyin[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Abiola, Emmanuel. Negotiating Patriarchal Structures: Polygamy and Female Agency in Lola Shoneyin’s The Secret Lives of Baba Segi’s Wives. Ibadan Journal of English Studies 7 (2018): 497–504.
  • Bámgbózé, Gabriel. "Beyond Gender Allegory: A Postcolonial Reading of Lola Shoneyin’s Poetry. Ibadan Journal of English Studies 7 (2018): 155-170.
  • Jegede, O. B. Subversive (re) writing and body poetics in Lola Shoneyin’s "So all the time I was sitting on an egg". Ibadan Journal of English Studies 7 (2018): 207–224.

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Lola Shoneyin". BBC World Service - Arts & Culture. BBC. 9 April 2010. Retrieved 2012-12-08. 
  2. Mary, Aborele (2019-02-26). "Popular Nigerian Literary Icon, Lola Shoneyin, Clocks 45". Welcome To PublicFace Magazine (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-30. 
  3. "An Interview with Lola Shoneyin, African Writing Online [many literatures, one voice]; Issue No. 9". www.african-writing.com. Retrieved 2020-05-30. 
  4. "Lola Shoneyin". Casafrica (in Èdè Sípáníìṣì). 2021-02-24. Retrieved 2022-10-12. 
  5. Africa39 list of artists, Hay Festival.
  6. "Lola Shoneyin". PEN America (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2015-01-07. Retrieved 2020-05-30. 
  7. "Lola Shoneyin". David Higham Associates (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-30. 
  8. Muoka, Chidera (26 November 2017). "Lola Shoneyin: Writer, Thinker, Creator". Retrieved 23 May 2018. 
  9. III, Editorial (2020-04-10). "Ake Arts and Book Festival moves online" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-30. 
  10. Edoro, Ainehi (30 December 2017). "The 2017 Brittle Paper African Literary Person of the Year Is Lola Shoneyin". Brittle Paper. https://brittlepaper.com/2017/12/lola-shoneyin-2017-brittle-paper-person-year/. Retrieved 20 August 2019. 
  11. Shoneyin, Lola (2010-03-20). "Polygamy? No thanks". The Guardian. Retrieved 2012-12-08. 
  12. "Mayowa and The Masquerades | Cassava Republic Press" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2018-05-11. Retrieved 2022-10-12. 
  13. "Nostalgia is an Extreme Sport: An essay from the collection, Of This Our Country". HarperCollins (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2022-10-12. 
  14. "Baba Segi, ses épouses, leurs secrets | Actes Sud". www.actes-sud.fr. Retrieved 2022-10-12. 
  15. "The Secret Lives of Baba Segi's Wives". Serpent's Tail (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-30. 
  16. Armitstead, Claire (2011-03-16). "Orange prize for fiction 2011: the longlist - gallery" (in en-GB). The Guardian. ISSN 0261-3077. https://www.theguardian.com/books/gallery/2011/mar/16/orange-prize-longlist. 
  17. "Author". HarperCollins Publishers: World-Leading Book Publisher (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-30. 
  18. "SPLA | Lola Shoneyin". www.spla.pro. Retrieved 2020-05-30. 
  19. Nigeria, Media (2018-06-05). "Biography Of Lola Shoneyin". Media Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-30. 
  20. 20.0 20.1 "Lola Shoneyin". Africa Book Club (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2012-03-04. Archived from the original on 2020-08-03. Retrieved 2020-05-30. 
  21. "notes on contributors". www.sentinelpoetry.org.uk. Archived from the original on 2020-08-03. Retrieved 2020-05-30. 
  22. "An Interview with Lola Shoneyin, African Writing Online [many literatures, one voice]; Issue No. 9". www.african-writing.com. Retrieved 2020-05-30.