Ngozi Okonjo-Iweala

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́


Ngozi Okonjo-Iweala
Minister of Finance
In office
17 August 2011 – 29 May 2015
ÀàrẹGoodluck Jonathan
AsíwájúOlusegun Olutoyin Aganga
Arọ́pòKemi Adeosun
In office
15 July 2003 – 21 June 2006
ÀàrẹOlusegun Obasanjo
AsíwájúAdamu Ciroma
Arọ́pòNenadi Usman
Coordinating Minister for the Economy
In office
17 August 2011 – 29 May 2015
ÀàrẹGoodluck Jonathan
AsíwájúOlusegun Olutoyin Aganga
Arọ́pòPosition abolished
Minister of Foreign Affairs
In office
21 June 2006 – 30 August 2006
ÀàrẹOlusegun Obasanjo
AsíwájúOluyemi Adeniji
Arọ́pòJoy Ogwu
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí13 Oṣù Kẹfà 1954 (1954-06-13) (ọmọ ọdún 69)
Ogwashi Ukwu, Nigeria
EducationHarvard University (BA)
Massachusetts Institute of Technology (MA, PhD)

Ngozi Okonjo-Iweala tí wọ́n bí ní ọjọ́ kẹtàlá oṣù kẹfà ọdún 1954 jẹ́ onímọ̀ ètò ìṣúná, ó sì tún jẹ́ Alákòóso fún ètò ìnáwó àti Alákòóso fún ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèrè tẹ́lẹ̀ fún orílẹ̀-èdè Njíríà [1]. Ó Jẹ́ ìkan láàárín àwon adarí ni Standard Chartered Bank, Twitter, Global Alliance for Vaccines and Immunizations àti African Risk Capacity (ARC).[2]Okonjo - Iweala tí si ṣé gẹ́gẹ́ bí ojisẹ nípa ọ̀rọ̀ owó ni ẹ méjì ni abẹ àkóso àwọn Ààrẹ ilẹ̀ Nàìjíríà tẹ́lẹ̀, Olusegun Obasanjo àti Goodluck Jonathan.[3]

Ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé àti ètò-ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bíi sì Ogwashi-Ukwu ni ìpínlè Delta ni Nàìjíríà. Bàbá rẹ̀ ni Professor Chukwuka Okonjo tí ó jẹ́ ọba láti ìdílé Obahai ni Ogwashi-Ukwu.[4] Ó lọ sí ilé ẹ̀kọ́ Queen's School ni Enugu, St. Anne's School ni Ìbàdàn àti International School ni Ibadan. Ó lọ sí ilé ẹ̀kọ́ gíga tí Harvard University ni USA ni ọdún 1978, ó sì gboyè nínú Economics ni ọdún 1976.[5] Ní ọdún 1981, ó gbà PhD nínú regional economics and development láti Massa Institute of Technology (MIT).[6] Ó gbà iranlọwọ láti ọ̀dọ̀ American Association of University Women tí ó fi tẹ síwájú nínú ẹ̀kọ́ rẹ.[7] Ó fé Dr. Ike bá Iweala, wọn si bíi ọmọ mẹrin.[8][9][10]

Iṣẹ́[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Okonjo Iweala tí si ṣé fun ilé ifowopamo tí agbaye fún ọdún meedọgbọn, ó sì gbà ipò kejì gẹ́gẹ́ bí adarí.[11] Ní ọdún 2010, ó di alaga fún Idà replenishment, èyí tí wọn fi fún $49.3 billion fún àwọn orílẹ̀ èdè tó tálákà jùlọ.[12][13] Ní ìgbà tí ó wà ní ilé ifowopamo àgbáyé, ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ Effective Development Cooperation with Africa. Okonjo ṣe minisita fún ọ̀rọ̀ owo ni Nàìjíríà ni ẹ méjì, ó sì tún ṣe minisita fún ètò ọ̀rọ̀ ilẹ̀ òkèèrè.[14] Òun ni obìnrin àkọ́kọ́ tí ó má kókó dé ipò náà. Óun lọ síwájú ìjíròrò pẹlu Paris Club, èyí tí ó fi jẹ ki wọn fagilé gbèsè $30billion tí Nàìjíríà jẹ.[15] Ní ọdún 2003, ó gbìyànjú láti jẹ ki idagbasoke wá nínú owó ti Nàìjíríà gbà nípa títa èpò ròbì, ó ṣe òfin pé tí wọn ba tá iye owó kàn, pé kí wọn fi sì ilẹ̀ ifowapamo.[16] Ó tun ṣe ìfihàn àwọn owó tí ipinle kàn kán gba sínú ìwé ìròyìn.[17] [18] Pẹlu àtìlẹyìn láti ọwọ́ ilé ifowopamo agbaye àti IMF tí ìjọba Nàìjíríà, ó dẹkùn jìbìtì tí àwọn kàn ṣe nípa gbígbà owó fún àwọn òṣìṣẹ́ tí kò sì.[19] Ó di adarí fún ile ifowopamo agbaye ni osù Kejìlá ọdún 2007.[20][21] Ní ọdún 2011, wọn tún fi jẹ minista fún ọ̀rọ̀ owó ni ìgbà kejì.[22] Ó pèsè ìṣe fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ èèyàn nípa ètò Youth Enterprise with Innovation (YouWIN),[23] ó sì rán àwọn obìnrin àti ọ̀dọ́ nípa ètò Growing Girls and Women in Nigeria (GWIN).[24][25] Ó ri ọ̀pọ̀lọpọ̀ wàhálà nígbà tí wón fi owó lè epo ni 2012.[26][27] Okonjo je ìkan lára àwọn alaga fún Global Commission for the Economy and Climate[28] àti Partnership for Effective Development Cooperation.[29] Ní ọdún 2015 - 2016, ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ International commission on Financing Global Education Opportunities. Okonjo - Iweala ni oludasile NOI-Polls[30] àti Centre for the study of Economics of Africa (C-SEA).[31] Ní ọdún 2012, ó du ipò olùdarí fún ilé iṣẹ́ ifowopamo tí agbaye.[32][33] Ní ọdún 2019, ó dára pọ̀ mọ́ ẹgbẹ́ UNESCO's International Commission on the Future of Education.[34] Ní ọdún 2020, olùdarí IMF, Kristalina Georgieva fi Okonjo ṣe ikan lára àwọn ònímoran fún àwọn ìdojúkọ nínú ètò ìmúlò wọn.[35] African Union náà fi ṣe aṣojú pàtàkì fún wọn láti lè dẹ́kun ipa tí àrùn Corona Virus ni lórí ọ̀rọ̀ aje tí àgbègbè náà.[36]

Ẹgbẹ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ọdún Ẹgbẹ́ Ipò Ref
2017 Japan International Cooperation Agency Ọmọ ẹgbẹ́ [37]
2016 Asian Infrastructure Investment Bank Ọmọ ẹgbẹ́ [38]
2016 GAVI Alága
(2003-2006, 2011-2015) African Development Bank Ìkan laarin awọn adarí [39]
2018 Twitter Ìkan laarin awọn adarí [40] [41]
2017 Standard Chartered PLC Ìkan laarin awọn adarí [42]
2015 Lazard Onímòràn pàtàkì [43]
2019 Carnegie Endowment for International Peace Ọmọ ẹgbẹ́ [44]
2018 Bloomberg New Economy Forum Ọmọ ẹgbẹ́ [45]
2014 Results for Development (R4D) Ọmọ ẹgbẹ́ [46][47]
2014 Women's World Banking Ọmọ ẹgbẹ́ [48]
2013 The B Team Ọmọ ẹgbẹ́ [49][50]
2007 Friends of the Global Fund Africa Ọmọ ẹgbẹ́ [51]
2007 Global Financial Integrity (GFI) Ọmọ ẹgbẹ́ [52]
2017 African Risk Capacity Alága [53]
African University of Science and Technology Alága
Georgetown Institute for Women Ọmọ ẹgbẹ́ [54]
Global Business Coalition for Education Ọmọ ẹgbẹ́ [55]
Mandela Institute for Development Studies (MINDS) Ọmọ ẹgbẹ́ [56]
Mercy Corps Ọmọ ẹgbẹ́ [57]
Nelson Mandela Institution Alága [58]
2013 One Campaign Ọmọ ẹgbẹ́ [59]
Oxford Martin School Ọmọ ẹgbẹ́ [60]
Vital Voices Ọmọ ẹgbẹ́ [61]

Ìdànimọ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Okonjo-Iweala gba òye ẹ̀yẹ láti ọwọ́ ilé ẹ̀kọ́ gíga merin lélógún tí University of Pennsylvania (2013),[62] Yale University (2015),[63] Amherst College (2009)[64] Trinity College, Dublin (2007)[65] Brown University (2006),[66] Colby College (2007).,[67] Northern Caribbean University, Jamaica, Abia State University, Delta State University, Abraka, Oduduwa University, Babcock University, Universities of Port Harcourt, Calabar, ati Ife (Obafemi Awolowo) ati Tel Aviv University.[68]

Ẹ̀bùn[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ọdún Ẹ̀bùn Ref
2017 Howard University - Vanguard Award
2014 Fortune top 50 Greatest World Leaders [69]
2017 Madeleine K. Albright Global Development Award, Aspen Institute
2015 Power with Purpose Award, Devex Development Communications Network
2016 Global Fairness Award, Global Fairness Initiative
2011 President of the Italian Republic Gold Medal, Pia Manzu Centre
2011 Global Leadership Award, Chicago Council on Global Affairs
2010 Global Leadership Award, Columbia University School of International and Public Affairs
2010 Bishop John T. Walker Distinguished Humanitarian Service Award
2004 TIME’s European Heroes Award
2004 Finance Minister of the Year, Africa Investor Magazine
2004 Finance Minister of the Year for Africa and the Middle East, The Banker
2005 Global Finance Minister of the Year, Euromoney
2005 Finance Minister of the Year for Africa and the Middle East, Emerging Markets Magazine
2014 Top 100 Most Influential People in the World (Time)
2011 & 2012 The Top 100 Global Thinkers(Foreign Policy) [70]
2011, 2012, 2013 and 2014 The Top 100 Most Powerful Women in the World (Forbes)
2012 The Top 3 Most Powerful Women in Africa (Forbes)
2011 the Top 10 Most Influential Women in Africa (Forbes)
2011 The Top 100 Women in the World (The Guardian)
2011 The Top 150 Women in the World (Newsweek)
2011 The Top 100 most inspiring people in the World Delivering for Girls and Women (Women Deliver)


Ìwé tíì ó kọ[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  • Fighting Corruption is Dangerous : The story behind the headlines - A frontline account from Nigeria's former finance minister, Ngozi Okonjo-Iweala, of how to fight corruption and lessons learned for governance and development. Published by MIT Press, (2018).[71] [72]
  • Okonjo-Iweala, Ngozi. Reforming the unreformable : lessons from Nigeria (First MIT Press paperback ed.). Cambridge, Massachusetts. ISBN 978-0-262-01814-2. LCCN 2012008453. OCLC 878501895. OLOL25238823M. 
  • Shine a Light on the Gaps – an essay on financial inclusion for African Small Holder Farmers, published by Foreign Affairs, (2015), co-authored with Janeen Madan
  • Funding the SDGs: Licit and Illicit Financial Flows from Developing Countries, published by Horizons Magazine, (2016)
  • Sallah, Tijan M.; Okonjo-Iweala, Ngozi (2003). Chinua Achebe, teacher of light : a biography. Trenton, NJ: Africa World Press. ISBN 1-59221-031-7. LCCN 2002152037. OCLC 50919841. OLOL3576773M. 
  • Okonjo-Iweala, Ngozi, ed (2003). The debt trap in Nigeria : towards a sustainable debt strategy. Trenton, NJ: Africa World Press. ISBN 1-59221-000-7. LCCN 2002007778. OCLC 49875048. OLOL12376413M. 
  • Want to Help Africa? Do Business Here – A Ted Talk delivered March 2007[73]
  • Aid Versus Trade – A Ted Talk delivered June 2007[74]
  • Don't Trivialise Corruption, Tackle It – A Tedx Euston Talk delivered January 2013[75]

Àwòrán rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]


Àwọn Itọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Ngozi Okonjo-Iweala makes history at WTO" (in en-GB). BBC News. 2021-03-01. https://www.bbc.com/news/world-africa-54903788. 
  2. "ARC Agency Governing Board – African Risk Capacity" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-12. 
  3. "ARC Agency Governing Board – African Risk Capacity" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-12. 
  4. "Okonjo reminiscences". mathshistory.st-andrews.ac.uk. Retrieved 2020-05-12. 
  5. "Ngozi Okonjo-Iweala, former finance minister of Nigeria and former managing director of the World Bank, will deliver the 2020 Graduation Address". www.hks.harvard.edu (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-12. 
  6. Okonjo-Iweala, Ngozi (1981) (in English). Credit policy, rural financial markets, and Nigeria's agricultural development (Thesis). Massachusetts Institute of Technology. OCLC 08096642. 
  7. "Nigeria receives its first sovereign credit ratings". Center for Global Development. February 9, 2006. Retrieved 8 May 2017. 
  8. "Ngozi Okonjo Iweala and her son Uzodinma". The Sunday Times. August 20, 2006. https://www.thetimes.co.uk/article/ngozi-okonjo-iweala-and-her-son-uzodinma-0pnwk99g8s5. Retrieved March 30, 2019. 
  9. "Dr. Ngozi Okonjo-Iweala". The B Team. 15 September 2016. Archived from the original on 12 June 2017. Retrieved 8 May 2017.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  10. Dinitia Smith (November 24, 2005), Young and Privileged, but Writing Vividly of Africa's Child Soldiers New York Times.
  11. "Ngozi Okonjo-Iweala". World Bank Live (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2013-10-02. Retrieved 2020-05-12. 
  12. "World Bank's Fund for The Poorest Receives Almost $50 Billion in Record Funding". 15 December 2010. http://www.worldbank.org/en/news/press-release/2010/12/15/world-banks-fund-for-the-poorest-receives-almost-50-billion-in-record-funding. Retrieved 24 September 2018. 
  13. Commission on Effective Development Cooperation with Africa Folketing.
  14. "Ngozi Okonjo-Iweala". Forbes (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-12. 
  15. "Nigerian Debt Relief". Center for Global Development. Retrieved 8 May 2017. 
  16. "The African State and Natural Resource Governance in the 21st Century" (PDF). The North-South Institute. Archived from the original (PDF) on 18 June 2019. Retrieved 16 May 2020. 
  17. "Nigeria’s Experience Publishing Budget Allocations: A Practical Tool to Promote Demand for Better Governance" (PDF). World Bank. 
  18. Songwe, Vera; Francis, Paul; Rossiasco, Paula; O'Neill, Fionnuala; Chase, Rob (2008-10-01) (in en). Nigeria's experience publishing budget allocations : a practical tool to promote demand for better governance. pp. 1–4. http://documents.worldbank.org/curated/en/220031468288952944/Nigerias-experience-publishing-budget-allocations-a-practical-tool-to-promote-demand-for-better-governance. 
  19. "ICT4D Strategic Action Plan Implementation - Status Update and Illustrations Book" (PDF). Archived from the original (PDF) on 19 August 2016. Retrieved 8 May 2017.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  20. "Ngozi Okonjo-Iweala". World Bank Live (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2013-10-02. Retrieved 2020-05-12. 
  21. Okonjo-Iweala, Ngozi (2018-04-04). "Ngozi Okonjo-Iweala". Brookings (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-12. 
  22. "Ngozi Okonjo-Iweala, Coordinating Minister of the Economy and Minister of Finance: Interview". Oxford Business Group. 
  23. David McKenzie (8 September 2015). "What happens when you give $50,000 to an aspiring Nigerian entrepreneur?". Impact Evaluations. Retrieved 8 May 2017. 
  24. "GWiN (Growing Girls and Women in Nigeria) Gets the Limelight!". Archived from the original on 26 May 2015. Retrieved May 15, 2017.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  25. "Rebasing Makes Nigeria Africa's Biggest Economy". 5 April 2014. Retrieved 8 May 2017. 
  26. "Nigeria unions to resist 'criminal' fuel price hike". BBC News. 12 May 2016. https://www.bbc.com/news/world-africa-36274402. Retrieved 8 May 2017. 
  27. "Ngozi Okonjo-Iweala appointed Chair-elect of Gavi Board". Gavi.org. Archived from the original on 15 April 2017. Retrieved 8 May 2017.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  28. "Members of the Global Commission". NewClimateEconomy.net. Retrieved April 17, 2017. 
  29. "Global Partnership for Effective Development Co-operation Media Guide" (PDF). Archived from the original (PDF) on 24 February 2017. Retrieved 8 May 2017.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  30. "Our Founder". Archived from the original on 6 July 2017. Retrieved 8 May 2017.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)
  31. "Center for the Study of Economies of Africa Homepage". Center for the Study of Economies of Africa. 
  32. "Managing Director of The World Bank, Dr. Ngozi Okonjo-Iweala, Visiting Turkey". World Bank (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-05. 
  33. Elizabeth Flock, Ngozi Okonjo-Iweala, World Bank presidential candidate, says she would focus on job creation, Washington Post (April 9, 2012).
  34. International Commission on the Futures of Education UNESCO.
  35. Andrea Shalal and David Lawder (April 10, 2020), IMF's Georgieva creates external advisory panel on pandemic Reuters.
  36. Emma Rumney (April 12, 2020), African Union appoints ex-Credit Suisse boss as envoy for virus support Reuters.
  37. First Meeting of the International Advisory Board Archived 9 May 2020 at the Wayback Machine. Japan International Cooperation Agency (JICA), press release of July 10, 2017.
  38. "International Advisory Panel Holds Inaugural Meeting". Asian Infrastructure Investment Bank (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-03-19. 
  39. 2013 Annual Report African Development Bank (AfDB).
  40. "Tweet by @jack". twitter.com. 19 July 2018. Retrieved 24 September 2018. 
  41. "Twitter Appoints Ngozi Okonjo-Iweala and Robert Zoellick to Board of Directors". PR Newswire. Jul 19, 2018. 
  42. "Okonjo-Iweala named director at UK bank - Vanguard News". Vanguard News (Vanguard News). 28 July 2017. http://www.vanguardngr.com/2017/07/okonjo-iweala-named-director-uk-bank/. Retrieved 5 August 2017. 
  43. "Ngozi Okonjo-Iweala". Washington Speakers Bureau. Archived from the original on 18 March 2020. Retrieved 8 May 2017. 
  44. Carnegie Endowment for International Peace Board of Trustees Welcomes Five New Members Carnegie Endowment for International Peace, June 6, 2019.
  45. Advisory Board Bloomberg New Economy Forum.
  46. Board of Directors Results for Development (R4D)
  47. Nigerian Finance Minister Ngozi Okonjo-Iweala Joins R4D Board of Directors Results for Development (R4D), press release of May 8, 2014.
  48. African leaders commit to economic empowerment for low-income women Women's World Banking, press release of November 24, 2014.
  49. Leaders The B Team.
  50. Richard Branson and Jochen Zeitz reveal The B Team Leaders and kick-start a Plan B for business The B Team, press release of June 13, 2013.
  51. Friends of The Global Fund Africa officially launched Global Fund to Fight AIDS, Tuberculosis and Malaria, press release of February 12, 2007.
  52. GFI Advisory Board Member, Ngozi Okonjo-Iweala, to Be Nominated for World Bank Presidency Global Financial Integrity (GFI), press release of March 22, 2012.
  53. "ARC Agency Governing Board". African Risk Capacity. October 29, 2016. 
  54. Advisory Board Georgetown Institute for Women, Peace and Security.
  55. Advisory Board Global Business Coalition for Education.
  56. Advisory Board Mandela Institute for Development Studies (MINDS).
  57. Global Leadership Council Mercy Corps.
  58. Board of Directors Archived 17 February 2021 at the Wayback Machine. Nelson Mandela Institution.
  59. Michael Elliott (June 25, 2013), The ONE campaign does not drown out African voices The Guardian.
  60. Governance Oxford Martin School.
  61. Global Advisory Council Archived 1 April 2020 at the Wayback Machine. Vital Voices.
  62. "Vice President Biden to speak at Penn's 257th Commencement | Penn Current". penncurrent.upenn.edu (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). March 14, 2013. Retrieved 2017-10-20. 
  63. "Yale awards nine honorary degrees at Commencement 2015". Yale News. 15 May 2015. Retrieved 8 May 2017. 
  64. "2009 Honorees | Ngozi Okonjo-Iweala". www.amherst.edu (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Archived from the original on 23 February 2018. Retrieved 2017-10-20. 
  65. "Honorary Degree Recipients". tcd.ie. Retrieved 8 May 2017. 
  66. "Brown University will confer eight honorary degrees on May 28". brown.edu. Retrieved 8 May 2017. 
  67. "Ngozi Okonjo-Iweala | Commencement". www.colby.edu (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2017-10-20. 
  68. "Photo News: Okonjo-Iweala bags honorary PhD from Tel Aviv varsity". P.M. News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2019-05-17. Retrieved 2019-05-18. 
  69. "Ngozi Okonjo-Iweala". Fortune (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-05. 
  70. "Ngozi Okonjo-Iweala". Center For Global Development (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-12. 
  71. "Fighting Corruption Is Dangerous by Ngozi Okonjo-Iweala"Paid subscription required. Financial Times. Retrieved 27 July 2018. 
  72. Okonjo-Iweala, Ngozi. Fighting corruption is dangerous : the story behind the headlines. Cambridge, Massachusetts. ISBN 978-0-262-03801-0. LCCN 2017041524. OCLC 1003273241. OLOL27372326M. 
  73. "Want to help Africa? Do business here". TED. Retrieved 8 May 2017. 
  74. "Aid versus trade". TED. Retrieved 8 May 2017. 
  75. "Don't trivialise corruption, tackle it: Ngozi Okonjo-Iweala at TEDxEuston". youtube (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-03-19.