Nigeria Ministry of Education

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Ilé-iṣẹ́ àpapọ̀ ẹ̀kọ́ tí wọ́n máa ń pè ní (Federal Ministry of Education) jẹ́ apá kan ti àwọn ilé-iṣẹ́ àpapọ̀ Naijiria (Federal Ministries of Nigeria) tí ó ń ṣe ìtọ́sọ́nà ètó-ẹ̀kọ́ ní Nàìjíríà. Ó wà ní Block 5A (8th Floor), Federal Secretariat Complex, Shehu Shagari Way, Central Area, P.M.B. 146, Garki, Abuja.

Ìtàn[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ààrẹ Muhammadu Buhari yan Adamu Adamu, gbajúgbajà oníròyìn gẹ́gẹ́ bí mínísítà fún ètò ẹ̀kọ́ ní oṣù kọkànlá ọdún 2015.[1]

Iṣẹ́ Wa[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

" Ìpinnu wa ni láti lo ètò-ẹ̀kọ́ gẹ́gẹ́ bí ohun èlò fún ìtèsíwájú ìdàgbàsókè gbogbo àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà sí agbára wọn ní kíkún, fún ìgbéga ti orílẹ̀-èdè tí ó lágbára, tiwa-n-tiwa, dọ́gbadọ́gba, tí ó ní ìlọsíwájú, tí a kò pin àti àìbíkítà orílẹ̀-èdè aláṣẹ lábẹ́ Ọlọ́run."[2]

Ilé Iṣẹ́[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Àwọn isẹ́ rẹ̀ pẹ̀lú:

  • al policy on education.
  • Collecting and collating data for purposes of educational planning and financing.
  • Maintaining uniform standards of education throughout the country.
  • Controlling the quality of education in the country through the supervisory role of the Inspectorate Services Department within the Ministry.
  • Harmonizing educational policies and procedures of all the states of the federation through the instrumentality of the National Council on Education.
  • Effecting co-operation in educational matters on an international scale.

Ara ilé iṣẹ́ àti àwọn ìtọ́ka sí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Parastatal include:

(NBAIS), Kaduna.

  1. "Jubilation at Education Ministry as Adamu takes over". Nigeria. Archived from the original on 2016-03-04. Retrieved 2015-11-14. 
  2. "Home" (in en-US). FEDERAL MINISTRY OF EDUCATION. https://education.gov.ng/.