Obianuju Ekeocha

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Obianuju Ekeocha
Ọjọ́ìbí1979 (ọmọ ọdún 44–45)
Owerri, Nigeria
Ẹ̀kọ́Hematology
Biomedical science
Iléẹ̀kọ́ gíga
Iṣẹ́Author
Scientist
Notable workOpen Letter to Melinda Gates[1]

Obianuju Ekeocha /θj/, tí àwọn ènìyàn mọ̀ sí Uju (a bi ní odun 1979), jẹ́ onímọ̀ Sáyẹ́nsì ọmọ orílè-èdè Nàìjíríà tí ó ń gbé ní Ilẹ̀ọba Aṣọ̀kan.[2] Òun ni ọ̀lùdásílẹ̀ àti ààrẹ "Culture of Life Africa".[3][4]

Ìtàn rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Ekeocha ń gbé ní orílẹ̀ èdè Ilẹ̀ọba Aṣọ̀kan[5] ẹ̀ka ibi tí ó ti ń síse ni ẹ̀ka àwọn tí ó ń wo ẹ̀jẹ̀ fún àìsàn, kòkòrò àti àwọn nkan míràn. Ní ọdún 2016, wón fun ní isẹ́ sí ilé ìwòsàn ní Ilẹ̀ọba Aṣọ̀kan. Ó jẹ́ ara ìjọ Kátólíìkì làti Ìpìlẹ̀ ṣẹ̀ṣẹ̀ ayé rẹ̀ nígbà tí ó wà ní Nàìjíríà.[6]

Ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Obianuju lọ ilé-ìwé Federal Government Girls' College ti Owerri, kí ó tó tẹ̀ ẹ̀kọ́ rẹ̀ síwájú ní Yunifásítì ilẹ̀ Nàìjíríà, Nsukka, níbi tí ó ti gba àmì ẹyẹ Bachelor nínú ìmò Microbiology. Lẹ́yìn èyí ó lọ orílè-èdè Ilẹ̀ọba Aṣọ̀kan láti gbà àmì ẹyẹ master nínú ìmò Biomedical scienceYunifásítì East London.

Àwọn Ìtókasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Àṣìṣe ìtọ́kasí: Invalid <ref> tag; no text was provided for refs named kilgus191024
  2. "Obianuju Ekeocha". Catholic Answers. Retrieved 2020-11-19. 
  3. "Obianuju Ekeocha". Acton University (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-11-19. 
  4. "Obianuju Ekeocha: Founder & President of Culture of Life Africa". Culture of Life Africa. Retrieved 2021-02-12. 
  5. Àṣìṣe ìtọ́kasí: Invalid <ref> tag; no text was provided for refs named :02
  6. Feingold, Sophia (April 27, 2016). "Pro-Life in Africa: ‘What We Hold in Common Is This Value for Family’. Obianuju Ekeocha, founder and president of Culture of Life Africa, shares her continent’s long-held values.". National Catholic Register. http://www.ncregister.com/news/pro-life-in-africa-what-we-hold-in-common-is-this-value-for-family-990wcul7.  Retrieved February 24, 2022.