Oluchi Okorie

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Oluchi Mercy Okorie tí a bí ní ọjọ́ kejìdínlọgbọ̀n osù kẹjọ ọdún 1981 ní Ìlú Èkó jẹ́ agbábọ́ọ̀lù sínú agbọ̀n ti orílẹ̀-ède Nàìjíríà tẹ́lẹ̀ rí tí ó gbábọ́ọ̀lù fún First Bank BC àti ẹgbẹ́ orílẹ̀-ède Nàìjíríà . Ó ṣe aṣojú Nàìjíríà ní bi 2005, 2006 àti 2007 FIBA Africa Championship .

Oluchi Okorie
No. 7
Iwájú, Àárín
Personal information
Bornọjọ́ kejìdínlọgbọ̀n osù kẹjọ ọdún 1981
Ìlú Èkó, Nàìjíríà
NationalityỌmọ Ilẹ̀ Nàìjíríà
Career information
CollegeTexas State Bobcats

iṣẹ́ Ìdárayá síse[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Láti ogúnjọ́ sí ọjọ́ kejìdínlọ́gbọ̀n Oṣù kejìlá, ní gbọ̀ngàn eré ìdárayá inú ilé ní Abuja, Nàìjíríà tí wọ́n ti gbàlejò FIBA Africa Championship fún àwọn obìnrin ní ọdún 2005 . Níbi ayeye náà, Oluchi ló sojú orílẹ̀-ède Nàìjíríà tó sì gba ààmì ẹ̀yẹ wúrà.

Ní bi 2006 FIBA Africa Women's Club Champions Cup èyí tí ó kópa, Oluchi gba ààmì ẹ̀yẹ idẹ.

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]