Pelu Awofeso

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Pelu Awofeso
Orílẹ̀-èdèNigerian
Iṣẹ́Journalist, travel-writer, tour guide
Gbajúmọ̀ fúnTour guiding, travel writing
AwardsCNN/Multichoice African Journalists Award

Pelu Awofeso jẹ́ akọ̀ròyìn ọmọ orílẹ̀-edè Nàìjíríà, ó jẹ́ ọ̀ǹkọ̀wé nípa ìrìn-àjò àti àṣà, tó ń gbé ìlú Èkó, ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ó jáwẹ́ olúborí nínú ìdíje ti CNN/Multichoice ní Africa fún àmì-ẹ̀yẹ ti ẹ̀ka àwọn oníròyìn nípa ìrìn-àjò. Ní ọ̀pọ̀ ìgbà ní à ń ṣe àpèjúwe rẹ̀ gẹ́gé bíi "aṣáájú òǹkọ̀wé nípa ìrìn-àjò" [1] Ó tún jẹ́ òǹkọ̀wé tí a ṣatẹ̀jáde ìwé rẹ̀.[2]

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Pelu Awofeso: Nigeria’s foremost travel writer | MyWeku Tastes". MyWeku Tastes. 10 April 2016. Archived from the original on 6 November 2017. https://web.archive.org/web/20171106103928/http://mywekutastes.com/pelu-awofeso-nigerias-foremost-travel-writer/. 
  2. "Ajimobi, Tinubu urge journalists to be fearless". The Punch. Archived from the original on 2015-06-15. Retrieved 2015-06-13.  Unknown parameter |url-status= ignored (help)