Segun Abraham

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
ṣẹ́gun Abraham
Ọjọ́ìbíOlusegun Abraham
Oṣù Kejìlá 24, 1953 (1953-12-24) (ọmọ ọdún 70)
Ikare-Akoko, Ondo State, Nigeria
Orílẹ̀-èdèỌmọ orílẹ̀ èdè Nàìjíríà
Iléẹ̀kọ́ gígaTyndale University College and Seminary Institute of Directors
Iṣẹ́Olóṣèlú àti oníṣòwò
Ìgbà iṣẹ́1999–present
Political partyAll Progressives Congress
Olólùfẹ́Bunmi Abraham
Websitesegunabraham.com

şégun Abraham jẹ́ olóṣèlú àti gbajúmọ̀ oníṣòwò ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú All Progressives Congress Ó gbégbá ìbò tí ó sìn díje lábẹ́ lé nínú ẹgbẹ́ òṣèlú APC fún ipò gómìnà ìjọba Ìpínlẹ̀ Oǹdó ní Ọdún 2016, [1][2] ṣùgbọ́n kò wọlé, Ọ̀gbẹ́ni Rótìmí Akérédolú ni ó wọlé lábẹ́ òṣèlú APC

Àwọn ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]