Sola David-Borha

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Sola David-Borha
David-Borha in 2020
Ọjọ́ìbíOlusola Adejoke
Accra, Ghana
Orílẹ̀-èdèNigerian
Ẹ̀kọ́
Iṣẹ́CEO of African Regions, Standard Bank
Board member ofNigerian Economic Summit Group
University of Ibadan Business School
Redeemer's University
Coca-Cola HBC AG
Olólùfẹ́Married

Olusola Adejoke David-Borha jẹ́ olùdarí àgbà fún ilé ìfowópámọ́ Standard Bank tí ilẹ̀ Áfríkà láti ọdún 2017.[1][2][3] Ó jẹ́ olùdarí àgbà fún Stanbic IBTC Holdings títí di oṣù kìíní ọdún 2017. Ò jẹ́ adarí fún ẹgbẹ́ Nigerian Economic Summit Group láti ọdún 2015. Ó darapọ̀ mọ́ àwọn adarí IBTC ní oṣù keje ọdún 1994.[4] Ó jẹ́ ìkan láàrin àwọn adarí fún Coca-Cola HBC AG láti ọdún kẹfà ọdún 2015. Ó jẹ́ ìkan láàrin àwọn adarí ní ilé èkọ́ gíga Redeemer's University.[5]

Ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀ ayé àti ẹ̀kọ́ rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí David sí ilé Accra ní orílẹ̀ èdè Ghana. Ó padà sí Nàìjíríà nígbà tí ó wà ní ọmọ ọdún mẹ́rìnlá. Ó gboyè jáde láti ilé ẹ̀kọ́ gíga tí University of Ibadan nínú ìmò Economics ní ọdún 1981.[6] O jẹ ọmọ ẹgbẹ́ Chartered Institute of Bankers of Nigeria.[7]

Iṣẹ́[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

David-Borha bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ní ilé ìfowópámọ́ ti NAL Merchant Bank láti ọdún 1984 títí di ọdún 1989[8] kí ó tó wà darapọ̀ mọ́ ilé ìfowópámọ́ IBTC. Ní ọdún 2007, IBTC ati Stanbic Bank Group parapọ̀ láti di Stanbic IBTC Holdings, Sola sí jẹ̀ ìkan láàrin àwọn olùdarí wọn. Ní oṣù kìíní ọdún 2017, ó gba ipò olùdarí àgbà fún Standard Bank Group.[9] Ó jẹ́ adarí fún CR Services Credit Bereau Plc àti University of Ibadan Business School.[10] Ní ọdún 2016, ó gbà àmì ẹ̀yẹ gẹ́gẹ́ bí oníṣòwò bìnrin fún ilé West Áfríkà àti Áfríkà láti ọ̀dọ̀ All Africa Business Leaders Award.[11] Sola jẹ́ ìyàwó fún David-Borha, wọ́n sì tì bí ọmọ mẹ́ta.[12]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. Asu, 'Femi (3 July 2018). "Nigeria'll be among biggest beneficiaries of AfCFTA – David-Borha". Punch. https://punchng.com/nigeriall-be-among-biggest-beneficiaries-of-afcfta-david-borha/amp/. Retrieved 11 February 2019. 
  2. Financial Nigeria (27 January 2017). "Sola David-Borha appointed CEO of Standard Bank's Africa subsidiaries". Financial Nigeria. http://www.financialnigeria.com/sola-david-borha-appointed-ceo-of-standard-bank-s-africa-subsidiaries-sustainable-photovideo-details-688.html. Retrieved 11 February 2019. 
  3. Ojo, Omolola (10 April 2018). "STANDARD BANK TARGETS SENEGAL AS PART OF EXPANSION INTO FRANCOPHONE WEST AFRICA". The Nerve Africa. Archived from the original on 1 July 2019. https://web.archive.org/web/20190701093205/https://thenerveafrica.com/16793/standard-bank-ivory-coast-senegal-expansion-francophone-west-africa/. Retrieved 11 February 2019. 
  4. Staff Writer (2 February 2017). "Sola David-Borha appointed Standard Bank Group Africa CEO, Yinka Sanni appointed Stanbic IBTC Holdings CEO & Demola Sogunle appointed Stanbic IBTC Bank CEO". African Business Central. Archived from the original on 1 July 2019. https://web.archive.org/web/20190701093203/https://www.africanbusinesscentral.com/2017/02/02/sola-david-borha-appointed-standard-bank-group-africa-ceo-yinka-sanni-appointed-stanbic-ibtc-holdings-ceo-demola-sogunle-appointed-stanbic-ibtc-bank-ceo/. Retrieved 11 February 2019. 
  5. Alex, Remmy (29 January 2017). "Nigeria's Sola David-Borha Appointed As Standard Bank Chief Executive". Nigerian Bulletin. https://www.nigerianbulletin.com/threads/nigerias-sola-david-borha-appointed-as-standard-bank-chief-executive.231910/. Retrieved 11 February 2019. 
  6. Muir, Toni (13 December 2017). "Meet Standard Bank's new African Regions boss, Sola David-Borha". CFO South Africa. Archived from the original on 12 February 2019. https://web.archive.org/web/20190212012010/https://cfo.co.za/article/interview-standard-bank-african-regions-boss-sola-david-borha. Retrieved 11 February 2019. 
  7. "Sola David-Borha, Standard Bank Group Ltd: Profile and Biography - Bloomberg Markets". Bloomberg.com. Retrieved 2020-01-15. 
  8. Odusanya, Rachael (4 February 2018). "Successful businesswoman Sola David Borha: facts about her career and personal life". legit.ng. https://www.legit.ng/amp/1149918-sola-david-borha-husband-biography.html. Retrieved 11 February 2019. 
  9. Tijani, Mayowa (25 January 2017). "David-Borha resigns as CEO Stanbic IBTC Holdings, moves to Standard Bank". The Cable. https://www.thecable.ng/david-borha-resigns-ceo-stanbic-ibtc-holdings-moves-standard-bank/amp. Retrieved 11 February 2019. 
  10. MarketScreener. "Olusola Adejoke David-Borha - Biography". Marketscreener.com. Retrieved 2020-01-15. 
  11. Odusanya, Rachael (4 February 2018). "Successful businesswoman Sola David Borha: facts about her career and personal life". legit.ng. https://www.legit.ng/amp/1149918-sola-david-borha-husband-biography.html. Retrieved 11 February 2019. 
  12. Muir, Toni (13 December 2017). "Meet Standard Bank's new African Regions boss, Sola David-Borha". CFO South Africa. Archived from the original on 12 February 2019. https://web.archive.org/web/20190212012010/https://cfo.co.za/article/interview-standard-bank-african-regions-boss-sola-david-borha. Retrieved 11 February 2019.