Steve Ayorinde

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́
Steve Ayorinde
Former Lagos State Commissioner for Information & Stretegy; Tourism, Arts & Culture
In office
October 2015 – May 2019
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí9 Oṣù Keje 1970 (1970-07-09) (ọmọ ọdún 53)
Ibadan, Oyo State Nigeria
Alma materObafemi Awolowo University, University of Lagos, University of Leicester
ProfessionJournalist / Media Consultant

Steve Olúṣẹ̀yí Ayọ̀rìndé /θj/ (tí wọ́n bí lọ́dún 1970) jẹ́ kọmíṣọ́nnà-àná fún ètò ìrìn-afẹ́, iṣẹ́-ọ̀nà àti àṣà tí Ìpínlẹ̀-Èkó lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[1][2] Ṣáájú àkókò yìí, ó jẹ́ kọmíṣọ́nnà nípa ìròyìn àti ọgbọ́n-ọnnú nígbà ìṣèjọba gómìnà-àná tí Ìpínlẹ̀ náà, Akinwunmi Ambode lọ́dún 2015,[3][4][5] Bákan náà, ó ti fìgbà kan jẹ́ Ọ̀gá-àgbà tí ilé-isé ìwé-ìròyìn National Mirror, àti olóòtú ìwé-ìròyìn The Punch[6] ní Nàìjíríà.[7]

Bákan náà, Ayorinde jẹ́ ọ̀kan lára gbajúmọ̀ lámèyító nípa sinimá àti iṣẹ́-ọ̀nà, ti ó sì tún ti jẹ́ adájọ́-aláṣàyàn fún àmì-ẹ̀yẹ àgbáyé bíi Toronto International Film Festival, Cannes Film Festival, Berlin International Film Festival, AMAA àti Mumbai International Film Festival.[8]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "The Face Of Tourism In Lagos Will Change This Year By Seye Kehinde". The Lagos Daily News (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). 2018-02-07. Archived from the original on 2020-08-15. Retrieved 2020-05-24. 
  2. "MR. STEVE AYORINDE – HON. COMMISSIONER". Tourism, Arts & Culture - Lagos State Government (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-24. 
  3. Chika Ebuzor (12 November 2015). "Steve Ayorinde: Commissioner criticises media for culling The Economist's article on Ambode". 
  4. "Bamigbetan is Lagos’ New Information Commissioner!". Gidi News. 11 January 2018. Archived from the original on 6 September 2018. Retrieved 25 March 2023. 
  5. "Ambode swears in 23 commissioners". Vanguard News. 19 October 2015. 
  6. "Steve Ayorinde". 
  7. "Footprint of David | Advisory Board" (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2020-05-24. 
  8. "Steve Ayorinde". African Film Festival Inc.