Taoreed Lagbaja

Lát'ọwọ́ Wikipedia, ìwé ìmọ̀ ọ̀fẹ́

Àdàkọ:Use Nigerian English


Taoreed Lagbaja
Chief of Army Staff
Lọ́wọ́lọ́wọ́
Ó gun orí àga
19 June 2023
ÀàrẹBola Tinubu
AsíwájúFaruk Yahaya
Àwọn àlàyé onítòhún
Ọjọ́ìbí28 Oṣù Kejì 1968 (1968-02-28) (ọmọ ọdún 56)
Irepodun, Western State, Nigeria (now in Osun State)
Alma mater
Military service
Allegiance Nigeria
Branch/service Nigerian Army
Years of service1987–present
Rank Major general

Ọ̀gágun Major General Taoreed Abíọ́dún Lágbájá (ni wọ́n bí lọ́jọ́ kejìdínlọ́gbọ̀n oṣù kejì ọdún 1968) jẹ́ Ọ̀gágun-àgbà tí ó gboyè Major General nínú iṣẹ́ ológun orílẹ̀ - èdè Nigeria. Òun ni Ọ̀gágun-àgbà yányán àwọn ológun Nigeria, Chief of Army Staff.[1][2][3] He was appointed on 19 June 2023 by President Bola Tinubu to succeed Lieutenant General Faruk Yahaya.

Ìgbà èwe rẹ̀[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n bí Lágbájá ní ìlú Ìlobù ní ìjọba Ìbílẹ̀ Ìrẹ́pọ̀dùn ní Ìpínlẹ̀ Ọ̀sun lọ́jọ́ kejìdínlọ́gbọ̀n oṣù kejì ọdún 1968. Ó lo ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀ ayé rẹ̀ ní ìlú Òṣogbo, níbi tí ó ti kàwé àkọ́bẹ̀rẹ̀ ní ilé-ìwé St Charles Grammar School and Local Authority Teachers College.[4]

Iṣẹ́[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

Wọ́n gbà á sí ilé-ìwé àwọn ológun Nigerian Defence Academy ọdún 1987. Wọ́n fún un lóye ológun (Second Lieutenant) lọ́jọ́ kọkàndínlógún oṣù kẹsàn-án ọdún 1992 ẹgbẹ́ ológun Nigerian Infantry Corps.[4]

Àwọn Ìtọ́kasí[àtúnṣe | àtúnṣe àmìọ̀rọ̀]

  1. "Ogalla, Abubakar, Egbetokun, Lagbaja, Musa - Meet Nigeria new Service Chiefs". BBC News Pidgin. https://www.bbc.com/pidgin/tori-65954606. 
  2. Udeh, StellaO; Aguwa, EmmanuelN; Onwasigwe, ChikaN (2022). "Workplace burnout and psychological health of military personnel in a Nigerian barrack". Nigerian Journal of Medicine 31 (3): 302. doi:10.4103/njm.njm_31_22. ISSN 1115-2613. http://dx.doi.org/10.4103/njm.njm_31_22. 
  3. Ariemu, Ogaga (2023-06-20). "10 interesting things to know about new COAS, Maj Gen Lagbaja". Daily Post Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-06-20. 
  4. 4.0 4.1 Yusuf, Kabir (2023-06-20). "PROFILE: Major General Taoreed Lagbaja: New head of Nigerian Army". Premium Times Nigeria (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2023-06-20.